< Psalms 91 >

1 Ẹni tí ó gbé ibi ìkọ̀kọ̀ Ọ̀gá-ògo ni yóò sinmi ní ibi òjìji Olódùmarè.
Yüceler Yücesi'nin barınağında oturan, Her Şeye Gücü Yeten'in gölgesinde barınır.
2 Èmi yóò sọ nípa ti Olúwa pé, “Òun ni ààbò àti odi mi, Ọlọ́run mi, ẹni tí èmi gbẹ́kẹ̀lé”.
“O benim sığınağım, kalemdir” derim RAB için, “Tanrım'dır, O'na güvenirim.”
3 Nítòótọ́ òun yóò gbà mí nínú ìdẹ̀kùn àwọn pẹyẹpẹyẹ àti nínú àjàkálẹ̀-ààrùn búburú.
Çünkü O seni avcı tuzağından, Ölümcül hastalıktan kurtarır.
4 Òun yóò fi ìyẹ́ rẹ̀ bò mí, àti ni abẹ́ ìyẹ́ rẹ̀ ni èmi yóò ti rí ààbò; òtítọ́ rẹ̀ ni yóò ṣe ààbò àti odi mi.
Seni kanatlarının altına alır, Onların altına sığınırsın. O'nun sadakati senin kalkanın, siperin olur.
5 Ìwọ kì yóò bẹ̀rù nítorí ẹ̀rù òru, tàbí fún ọfà tí ń fò ní ọ̀sán,
Ne gecenin dehşetinden korkarsın, Ne gündüz uçan oktan, Ne karanlıkta dolaşan hastalıktan, Ne de öğleyin yok eden kırgından.
6 tàbí fún àjàkálẹ̀-ààrùn tí ń rìn kiri ní òkùnkùn, tàbí fún ìparun tí ń rìn kiri ní ọ̀sán gangan.
7 Ẹgbẹ̀rún yóò ṣubú ní ẹ̀gbẹ́ rẹ, ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ, ṣùgbọ́n kì yóò súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ.
Yanında bin kişi, Sağında on bin kişi kırılsa bile, Sana dokunmaz.
8 Ìwọ yóò máa wò ó pẹ̀lú ojú rẹ àti wo ìjìyà àwọn ẹni búburú.
Sen yalnız kendi gözlerinle seyredecek, Kötülerin cezasını göreceksin.
9 Nítorí ìwọ fi Olúwa ṣe ààbò rẹ, ìwọ fi Ọ̀gá-ògo ṣe ibùgbé rẹ.
Sen RAB'bi kendine sığınak, Yüceler Yücesi'ni konut edindiğin için,
10 Búburú kan ki yóò ṣubú lù ọ́, Bẹ́ẹ̀ ni ààrùnkárùn kì yóò súnmọ́ ilé rẹ.
Başına kötülük gelmeyecek, Çadırına felaket yaklaşmayacak.
11 Nítorí yóò fi àṣẹ fún àwọn angẹli nípa tìrẹ láti pa ọ́ mọ́ ní gbogbo ọ̀nà rẹ;
Çünkü Tanrı meleklerine buyruk verecek, Gideceğin her yerde seni korusunlar diye.
12 wọn yóò gbé ọ sókè ní ọwọ́ wọn, nítorí kí ìwọ má ba à fi ẹsẹ̀ rẹ gún òkúta.
Elleri üzerinde taşıyacaklar seni, Ayağın bir taşa çarpmasın diye.
13 Ìwọ yóò rìn lórí kìnnìún àti paramọ́lẹ̀; ìwọ yóò tẹ kìnnìún ńlá àti ejò ńlá ni ìwọ yóò fi ẹsẹ̀ tẹ̀ mọ́lẹ̀.
Aslanın, kobranın üzerine basıp geçeceksin, Genç aslanı, yılanı çiğneyeceksin.
14 “Nítorí ti ìfẹ́ rẹ sí mi, èmi yóò gbà ọ́; èmi yóò pa ọ́ mọ́, nítorí ìwọ jẹ́wọ́ orúkọ mi.
“Beni sevdiği için Onu kurtaracağım” diyor RAB, “Beni iyi tanıdığı için Ona kale olacağım.
15 Òun yóò pè mí, èmi yóò sì dá a lóhùn; èmi yóò wà pẹ̀lú rẹ̀ nínú ìpọ́njú, èmi yóò gbà á, èmi yóò sì bu ọlá fún un.
Bana seslenince onu yanıtlayacağım, Sıkıntıda onun yanında olacağım, Kurtarıp yücelteceğim onu.
16 Pẹ̀lú ẹ̀mí gígùn ni èmi yóò fi tẹ́ ẹ lọ́rùn, èmi yóò sì fi ìgbàlà mi hàn án.”
Onu uzun ömürle doyuracak, Ona kurtarışımı göstereceğim.”

< Psalms 91 >