< Psalms 91 >

1 Ẹni tí ó gbé ibi ìkọ̀kọ̀ Ọ̀gá-ògo ni yóò sinmi ní ibi òjìji Olódùmarè.
O KA mea noho iho ma kahi malu o ka Mea kiekie loa, E moe oia ma ke aka o ka Mea mana loa.
2 Èmi yóò sọ nípa ti Olúwa pé, “Òun ni ààbò àti odi mi, Ọlọ́run mi, ẹni tí èmi gbẹ́kẹ̀lé”.
E olelo aku au ia Iehova, Kuu puuhonua, kuu puukaua hoi; Kuu Akua, e paulele aku au ia ia.
3 Nítòótọ́ òun yóò gbà mí nínú ìdẹ̀kùn àwọn pẹyẹpẹyẹ àti nínú àjàkálẹ̀-ààrùn búburú.
Oiaio no, e hoopakele mai no oia ia'u i ka hei o ka mea hoohei, A me ka mai make ahulau.
4 Òun yóò fi ìyẹ́ rẹ̀ bò mí, àti ni abẹ́ ìyẹ́ rẹ̀ ni èmi yóò ti rí ààbò; òtítọ́ rẹ̀ ni yóò ṣe ààbò àti odi mi.
E uhi mai no oia ia oe i kona mau hulu, A e holo no oe malalo iho o kona mau ehen; No ka mea, o kona oiaio, he palekaua ia, a he paku no hoi.
5 Ìwọ kì yóò bẹ̀rù nítorí ẹ̀rù òru, tàbí fún ọfà tí ń fò ní ọ̀sán,
Aole oe e makau i ka mea hooweliweli i ka po; Aole hoi i ka pua e lele ana i ke ao;
6 tàbí fún àjàkálẹ̀-ààrùn tí ń rìn kiri ní òkùnkùn, tàbí fún ìparun tí ń rìn kiri ní ọ̀sán gangan.
Aole hoi i ka mai make e holoholo ana maloko o ka pouli; Aole no hoi i ka mai luku e hooneoneo ana i ke awakea.
7 Ẹgbẹ̀rún yóò ṣubú ní ẹ̀gbẹ́ rẹ, ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ, ṣùgbọ́n kì yóò súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ.
E hina no ka tausani ma kou aoao, A me na legeona ma kou aoao akau; Aole nae e bookokoke aku ia oe.
8 Ìwọ yóò máa wò ó pẹ̀lú ojú rẹ àti wo ìjìyà àwọn ẹni búburú.
E nana wale aku no kou mau maka, A e ike no oe i ka hoopaiia o ka poe hewa.
9 Nítorí ìwọ fi Olúwa ṣe ààbò rẹ, ìwọ fi Ọ̀gá-ògo ṣe ibùgbé rẹ.
No ka mea, ua hoolilo no oe ia Iehova, kuu puuhonua, I ka Mea kiekie hoi, i wahi noho ai nou;
10 Búburú kan ki yóò ṣubú lù ọ́, Bẹ́ẹ̀ ni ààrùnkárùn kì yóò súnmọ́ ilé rẹ.
Aole oe e loohia i ka hewa, Aole e hookokoke mai ka mea ino i kou halelewa.
11 Nítorí yóò fi àṣẹ fún àwọn angẹli nípa tìrẹ láti pa ọ́ mọ́ ní gbogbo ọ̀nà rẹ;
No ka mea, e kauoha mai no ia i kona poe anela nou, E malama ia oe ma kou mau aoao a pau.
12 wọn yóò gbé ọ sókè ní ọwọ́ wọn, nítorí kí ìwọ má ba à fi ẹsẹ̀ rẹ gún òkúta.
E kaikai lakou ia oe, ma ko lakou mau lima, O kuia kou wawae i ka pohaku.
13 Ìwọ yóò rìn lórí kìnnìún àti paramọ́lẹ̀; ìwọ yóò tẹ kìnnìún ńlá àti ejò ńlá ni ìwọ yóò fi ẹsẹ̀ tẹ̀ mọ́lẹ̀.
E hehi no hoi oe maluna o ka liona a me ka moomake; A e hahahi no hoi oe i ka liona opiopio a me ka moonui.
14 “Nítorí ti ìfẹ́ rẹ sí mi, èmi yóò gbà ọ́; èmi yóò pa ọ́ mọ́, nítorí ìwọ jẹ́wọ́ orúkọ mi.
No kona hoopili ana mai ia'u, e hoopakele aku wau ia ia; E hookiekie aku no hoi au ia ia, no ka mea, ua ike mai oia i ko'u inoa.
15 Òun yóò pè mí, èmi yóò sì dá a lóhùn; èmi yóò wà pẹ̀lú rẹ̀ nínú ìpọ́njú, èmi yóò gbà á, èmi yóò sì bu ọlá fún un.
E kabea mai no oia ia'u, a e pane aku au ia ia; Owau pu me ia maloko o ka popilikia; Na'u no ia e hoopakele ae, a e hoohanohano no hoi ia ia.
16 Pẹ̀lú ẹ̀mí gígùn ni èmi yóò fi tẹ́ ẹ lọ́rùn, èmi yóò sì fi ìgbàlà mi hàn án.”
E hoonui aku au i kona mau la, A e hoike aku no hoi au ia ia, i kou hoola.

< Psalms 91 >