< Psalms 45 >

1 Fún adarí orin. Tí ohun orin “Lílì.” Ti orin àwọn ọmọ Kora. Maskili. Orin ìgbéyàwó. Ọkàn mi mọ ọ̀rọ̀ rere gẹ́gẹ́ bí mo ṣe ń sọ ohun tí mo ti ṣe fún ọba ahọ́n mi ni kálámù ayára kọ̀wé.
Thaburi ya Ariũ a Kora Ngoro yakwa ĩiyũrĩtwo nĩ ũhoro mwega rĩrĩa ngũinĩra mũthamaki rwĩmbo rũrũ; rũrĩmĩ rwakwa no ta karamu ka mwandĩki ũrĩa mũũgĩ.
2 Ìwọ yanjú ju àwọn ọmọ ènìyàn lọ: a da oore-ọ̀fẹ́ sí ọ ní ètè: nítorí náà ni Ọlọ́run ṣe bùkún fún ọ láéláé.
Wee ũrĩ mũthaka mũno gũkĩra andũ othe, nacio iromo ciaku nĩciitĩrĩirio maũndũ ma ũtugi, kuona atĩ Ngai nĩakũrathimĩte nginya tene.
3 Gba idà rẹ mọ́ ìhà rẹ, ìwọ alágbára jùlọ wọ ara rẹ ní ògo àti ọláńlá.
Wĩohe rũhiũ rwaku rwa njora njohero, Wee njamba ĩno ĩrĩ hinya; wĩhumbe ũkaru waku o na ũnene.
4 Nínú ọláńlá rẹ, máa gẹṣin lọ ní àlàáfíà lórí òtítọ́, ìwà tútù àti òtítọ́; jẹ́ kí ọwọ́ ọ̀tún rẹ ṣe ohun ẹ̀rù.
Ũrĩ thĩinĩ wa ũnene waku thiĩ ũhaicĩte mbarathi, ũkĩhootanaga nĩ ũndũ wa ũhoro wa ma, na wa kwĩnyiihia, o na wa ũthingu; reke guoko gwaku kwa ũrĩo kuonanie ciĩko cia kũmakania.
5 Jẹ́ kí ọfà mímú rẹ̀ dá ọkàn àwọn ọ̀tá ọba lu jẹ́ kí àwọn orílẹ̀-èdè ṣubú sí abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.
Mĩguĩ yaku ĩrĩa mĩũgĩ nĩĩtheece thũ cia mũthamaki o ngoro-inĩ; ndũrĩrĩ nĩigwe magũrũ-inĩ maku.
6 Ọlọ́run láé, àti láéláé ni ìtẹ́ rẹ, ọ̀pá aládé ìjọba rẹ, ọ̀pá aládé òtítọ́ ni.
Wee Ngai, gĩtĩ gĩaku kĩa ũnene gĩgũtũũra tene na tene; mũthĩgi waku wa kĩhooto nĩguo ũgaatuĩka mũthĩgi wa ũthamaki waku.
7 Ìwọ fẹ́ olódodo, ìwọ sì kórìíra ìwà búburú nígbà náà Ọlọ́run, Ọlọ́run rẹ ti yàn ọ́ ṣe olórí àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ, nípa fífi àmì òróró ayọ̀ kùn ọ́.
Wee wendete ũthingu no ũgathũũra waganu; nĩ ũndũ ũcio Ngai, o we Ngai waku, nĩakwambararĩtie gũkĩra athiritũ aku othe na ũndũ wa gũgũitĩrĩria maguta ma gĩkeno.
8 Gbogbo aṣọ rẹ̀ ni ó ń rùn pẹ̀lú òjìá àti aloe àti kasia; láti inú ààfin tí a fi eyín erin ṣe orin olókùn tẹ́ẹ́rẹ́ mú inú rẹ̀ dùn.
Nguo ciaku ciothe inungĩte o manemane, na thubiri, na mũndarathini; nĩũrakenio nĩ aini a nyĩmbo na inanda cia nga marĩ ciikaro-inĩ cia mũthamaki iria igemetio na mĩguongo.
9 Àwọn ọmọbìnrin àwọn ọba wà nínú àwọn àyànfẹ́ rẹ̀, ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ ni ayaba náà gbé dúró nínú wúrà Ofiri.
Thĩinĩ wa andũ-a-nja aku arĩa atĩĩku harĩ na aarĩ a athamaki; mũhiki ũcio wa mũthamaki aikarĩte mwena waku wa ũrĩo egemetie na thahabu ya Ofiri.
10 Gbọ́ ìwọ ọmọbìnrin, ronú kí o sì dẹtí rẹ sí mi gbàgbé àwọn ènìyàn rẹ àti ilé baba rẹ.
Ta thikĩrĩria, wee mwarĩ ũyũ, wĩcũũranie na ũigue: Riganĩrwo nĩ andũ anyu o na nyũmba ya thoguo.
11 Bẹ́ẹ̀ ni ọba yóò fẹ́ ẹwà rẹ gidigidi nítorí òun ni olúwa rẹ kí ìwọ sì máa tẹríba fún un.
Mũthamaki nĩakenetio mũno nĩ ũthaka waku; mũtĩĩe, nĩgũkorwo nĩwe mwathi waku.
12 Ọmọbìnrin ọba Tire yóò wá pẹ̀lú ẹ̀bùn àwọn ọkùnrin ọlọ́rọ̀ yóò máa wá ojúrere rẹ̀.
Mwarĩ wa Turo nĩagakũrehera kĩheo, o nao andũ arĩa atongu mũno magatuĩka a kwĩyendithia harĩwe.
13 Gbogbo ògo ni ti ọmọbìnrin ọba ní àárín ilé rẹ̀, iṣẹ́ wúrà ọnà abẹ́rẹ́ ní aṣọ rẹ̀.
Mwarĩ wa mũthamaki no riiri mũtheri arĩ naguo arĩ thĩinĩ wa nyũmba yake, nguo yake ĩtumĩtwo na ndigi cia thahabu.
14 Nínú aṣọ olówó iyebíye ni a mú un tọ́ ọba wá, àwọn wúńdíá ẹgbẹ́ rẹ̀ tẹ̀lé e, wọ́n sí mú un tọ̀ ọ́ wá.
Aratwarwo harĩ mũthamaki ehumbĩte nguo ngʼemie; oimĩtwo thuutha nĩ airĩtu gathirange a thiritũ yake, na othe marooka kũrĩ we.
15 Wọ́n sì mú un wá pẹ̀lú ayọ̀ àti inú dídùn wọ́n sì wọ ààfin ọba.
Mararehwo na gĩkeno na ndũhiũ; nĩmatoonye nyũmba ya mũthamaki.
16 Ọmọ rẹ̀ ni yóò gba ipò baba rẹ̀ ìwọ yóò sì fi wọ́n joyè lórí ilẹ̀ gbogbo.
Ciana cianyu nĩcio igaacooka ithenya rĩa maithe manyu; ũkaamatua anene bũrũri-inĩ guothe.
17 Èmí yóò máa rántí orúkọ rẹ̀ ní ìran gbogbo, nígbà náà ni orílẹ̀-èdè yóò yìn ọ́ láé àti láéláé.
Nĩngũtũma ũtũũre ũririkanagwo nĩ njiarwa na njiarwa; nĩ ũndũ ũcio ndũrĩrĩ igaatũũra igũkumagia tene na tene.

< Psalms 45 >