< Psalms 14 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Aṣiwèrè wí nínú ọkàn rẹ̀ pé, “Ko sí Ọlọ́run.” Wọ́n díbàjẹ́, iṣẹ́ wọn sì burú; kò sí ẹnìkan tí yóò ṣe rere.
Az éneklőmesternek; Dávidé. Azt mondja a balgatag az ő szívében: Nincs Isten. Megromlottak, útálatosságot cselekedtek; nincs, a ki jót cselekedjék.
2 Olúwa sì bojú wolẹ̀ láti ọ̀run wá lórí àwọn ọmọ ènìyàn bóyá ó le rí ẹni tí òye yé, ẹnikẹ́ni tó ń wá Ọlọ́run.
Az Úr letekintett a mennyből az emberek fiaira, hogy meglássa, ha van-é értelmes, Istent kereső?
3 Gbogbo wọn sì ti yípadà, gbogbo wọn sì ti díbàjẹ́; kò sì ṣí ẹni tí ó ń ṣe rere, kò sí ẹnìkan.
Mindnyájan elhajlottak; egyetemben elromlottak, nincs, a ki jót cselekedjék, nincsen csak egy sem.
4 Ǹjẹ́ olùṣe búburú kò ha ní ìmọ̀? Àwọn tí ó ń pa ènìyàn mi jẹ bí ẹní jẹun; wọn kò sì ké pe Olúwa?
Nem tudják-é ezt mind a gonosztévők, a kik megeszik az én népemet, mintha kenyeret ennének, az Urat pedig segítségül nem hívják?
5 Wọ́n wà níbẹ̀, tí a bò mọ́lẹ̀ pẹ̀lú ẹ̀rù, nítorí Ọlọ́run wà ní àwùjọ àwọn olódodo.
Majd rettegnek rettegéssel, mert Isten az igaz nemzetséggel van!
6 Ẹ̀yin olùṣe búburú da èrò àwọn tálákà rú, ṣùgbọ́n Olúwa ni ààbò wọn.
A szegénynek tanácsát kicsúfoljátok, mert az Úr az ő bizodalma.
7 Ìgbàlà àwọn Israẹli yóò ti Sioni wá! Nígbà tí Olúwa bá mú ìkólọ àwọn ènìyàn rẹ̀ padà, jẹ́ kí Jakọbu kí ó yọ̀, kí inú Israẹli kí ó dùn!
Vajha eljőne Sionból Izráelnek a szabadítás! Mikor az Úr visszahozza népének foglyait, Jákób örül majd és vigad Izráel.

< Psalms 14 >