< Philippians 1 >

1 Paulu àti Timotiu, àwọn ìránṣẹ́ Jesu Kristi, Sí gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́ nínú Kristi Jesu tí ó wà ní Filipi, pẹ̀lú àwọn alábojútó àti àwọn díákónì:
Bulus ka-nge Timoti cangab kiristi Yeesu yã ciko nob kwamab wucake wo Fillibi ka-nge nubo tam ki nubo bwanten kwama tiye, ka-nge nubo durku lo wabbeu. ka-nge nobo durko ku wabbe.
2 Oore-ọ̀fẹ́ sí yín, àti àlàáfíà láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa, àti Olúwa wa Jesu Kristi.
luma kimen ka-nge fuwor neret tebe kwama nin ka-nge Teluwe Yeesu kiristi.
3 Mo ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run mi ní gbogbo ìgbà tí mo bá rántí yín.
mi bu kwama nin ka-ngeti diye no ma kwa kom ki nere di.
4 Nínú gbogbo àdúrà mi fún un yín, èmi ń fi ayọ̀ gbàdúrà,
kir-kir mor dilo minin kimen gwam, mi kwob dilo miti ki nero fuwor.
5 nítorí ìdàpọ̀ yín nínú ìyìnrere láti ọjọ́ kìn-ín-ní wá títí di ìsinsin yìí.
mi bu ka-ngeti dor nangenero bi mati wari mor fulen kere ka cikko ba teruwe ya ciko na wo.
6 Ohun kan yìí sá à dá mi lójú pé, ẹni tí ó ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rere nínú yín, yóò ṣe àṣepé rẹ̀ títí di ọjọ́ náà tí Jesu Kristi yóò dé.
miki bi kwamer neret wo ter nangen ken kimeneu an yaken ciko cwobka di kakuk Yeesu kiristi.
7 Gẹ́gẹ́ bí ó ti tọ́ fún mi láti ro èyí nípa gbogbo yín, nítorí tí mo fi yín sọ́kàn, bí mo tilẹ̀ wà nínú ìdè tàbí ìdáhùn ẹjọ́, àti ìfẹsẹ̀múlẹ̀ ìyìnrere, gbogbo yín jẹ́ alábápín oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run pẹ̀lú mi.
won digero ken nuwa nyo nure wuro dor kimer gwan, nyori miki kom gwam ner mir. kom yilam far nangene mi mor luma, ki bwaka miko ka-nge cerka dorek mik ka-nge tika ki bi kwan bifumero nin.
8 Nítorí Ọlọ́run ni ẹlẹ́rìí mi, bí mo ti ń ṣàfẹ́rí yín gidigidi nínú ìfẹ́ Jesu Kristi.
kwama warke mi, kuru kime gwam mi ciko mor cwika dur wo Yeesu kiristi ce.
9 Èyí sì ni àdúrà mi: pé kí ìfẹ́ yín lè máa pọ̀ síwájú àti síwájú sí i nínú ìfẹ́ àti ìmọ̀ ìjìnlẹ̀,
wo co dilo mi, cwika kime ko a yokten kab mor merangka ka-nge, ka-nge nyomko diger gwam.
10 kí ẹ̀yin kí ó lè ní òye ohun tí ó dára jùlọ; kí ó sì jásí òdodo àti aláìjẹ́ ohun ìkọ̀sẹ̀ títí di ọjọ́ dídé Jesu Kristi,
nyori na ko ciye ki dige yor yore gwam na kom yilam nobo ki bilengke, digero bwir mani kimen ya cika dige kiristi.
11 lẹ́yìn ìgbà ti ẹ ti kún fún àwọn ìwà òdodo láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi, fún ògo àti ìyìn Ọlọ́run.
dim ki bi tutti wucake wo bouti fiye Yeesu kiristi na duktangka ka-nge caklangka kwama.
12 Ǹjẹ́ èmi fẹ́ kí ẹ̀yin kí ó mọ̀, ará, pé ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí mi jásí àtẹ̀gùn sí ìlọsíwájú ìyìnrere.
mi cwi komti ki nyimi keb mibo, dige fiya yereu matikali fiye yokka fulen keret kwama.
13 Nítorí ìdí èyí, ó ti hàn gbangba sí gbogbo àwọn ẹ̀ṣọ́ ààfin àti sí àwọn ẹlòmíràn wí pé mo wà nínú ìdè fún Kristi.
bwaka miko mor kiristi bou ki filang nubo lo liya, nubo tõ nub tiyeu gwam, ka-nge kangum bo fiye ka-nge.
14 Nítorí ìdè mi, ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ará nínú Olúwa ni a ti mú lọ́kàn le láti sọ̀rọ̀ Ọlọ́run sí i pẹ̀lú ìgboyà àti láìbẹ̀rù.
kangum yitub beb, ki kinin yilam ki bi kwan neret mor Teluwebe ker bwaka miko, ciki nero kwamer ciya miko keroti man ki taiye.
15 Òtítọ́ ni pé àwọn ẹlòmíràn tilẹ̀ ń fi ìjà àti ìlara wàásù Kristi, ṣùgbọ́n àwọn ẹlòmíràn sì ń fi inú rere ṣe é.
kangum bo tok ker kiristi ki kor neret ki kwilki-kwilkiye. kangum bo ki nero ken.
16 Àwọn kan ń fi ìjà wàásù Kristi, kì í ṣe pẹ̀lú òtítọ́ inú, wọ́n ń gbèrò láti fi ìpọ́njú kún ìdè mi.
nubo ki biye wo ki ma ki cwika, ki nyomka ci bwayere na yilam kucang fulen keret.
17 Àwọn kan ẹ̀wẹ̀ si ń fi ìfẹ́ ṣe é, nítorí tí wọ́n mọ̀ pé a gbé mi dìde láti dá ààbò bo iṣẹ́ ìyìnrere.
nubo wo bwiye ki tok ker kiristi do mor cwika neret ciye, kebo dor bilen keret. ci kwatiri ciyan neye dotange ki fiya cuwo mi bwambwabe.
18 Kí ló tún kù? Kìkì í pé níbi gbogbo, ìbá à ní ìfẹ̀tànṣe tàbí ni ti òtítọ́ a sá à n wàásù Kristi, èmi sì ń yọ̀ nítorí èyí. Nítòótọ́, èmi ó sì máa yọ̀,
“la ye” diger win, mor digero gwam, bwen tano ciki ma ki cwerke kaka bilengke. cin tok fulen kwamaro, nyeu, min nuwa luma, ong min nuwa luma.
19 nítorí tí mo mọ̀ pé èyí ni yóò yọrí sí ìgbàlà fún mi láti inú àdúrà yín wá, àti ìfikún ẹ̀mí Jesu Kristi.
min nyimom wo a dok cerkamik mor dilo kime ka-nge tikali yuwa kwaman tangbe wo Yeesu kiristi.
20 Gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ ọkàn àti ìrètí mi pé kí ojú kí ó má ṣe ti mi ní ohunkóhun, ṣùgbọ́n kí èmi kí ó le máa ni ìgboyà ní ìgbà gbogbo àti nísinsin yìí, kí a lè ti ipasẹ̀ mi gbé Kristi ga lára mi, ìbá à ṣe pé mo wà láààyè, tàbí mo kú.
miki kuru kang yo neri mani ma nuwa kwenduwe ti, ka-nge ti ka kibi kwang, can ka-nge kicatecc, kiristi an fiya dur kwimi, bwar kaka'a mor dume.
21 Nítorí, ní ti èmi, láti wa láààyè jẹ́ Kristi, láti kú pẹ̀lú sì jẹ́ èrè fún mi.
minen “mu ki dumeri, kiristi, no bwar di yokka.
22 Ṣùgbọ́n bí èmi bá le è ṣe iṣẹ́ ti ó ni àpẹẹrẹ nípa wíwà láààyè nínú ara, ṣùgbọ́n ohun ti èmi ó yàn, èmi kò mọ̀.
mor bwiyeri, mi nintang wo ti gwam.
23 Ṣùgbọ́n èmi n ṣiyèméjì, nítorí ti èmi fẹ́ láti lọ kúrò nínú ayé yìí, láti wà lọ́dọ̀ Kristi; nítorí ó dára púpọ̀ jù:
la yilam digero bwaibwaye tiber digero wo yobeu. cwika miko na kũbo na ya'a yi ka-nge Yeesu, wo dige yore gwam,
24 síbẹ̀ láti wà láààyè jẹ́ àǹfààní nítorí tiyín.
nyeu yilam ki dume, tam nyo ker kimer.
25 Bí èyí sì ti dá mi lójú, mo mọ̀ pé èmi ó dúró, èmi ó sì máa wà pẹ̀lú yín fún ìtẹ̀síwájú àti ayọ̀ yín nínú ìgbàgbọ́,
wo min ciya ciko, min nyimom man yim nan bwanten ka-nge kom gwam dor caka kaba ka-nge bilantum mor bilengke.
26 kí ìṣògo yín kí ó lè di púpọ̀ gidigidi nínú Jesu Kristi, àti nínú mi nípa ìpadà wá mi sọ́dọ̀ yín.
nyori fiye mi wiye na kom fiya yokka mor kiristi Yeesu no bou kimen takri.
27 Ohun yówù kó ṣẹlẹ̀, ẹ jẹ́ kí ìgbé ayé yín ri gẹ́gẹ́ bí ìyìnrere Kristi: pé yálà bi mo tilẹ̀ wá wò yín, tàbí bí èmi kò wá, kí èmi kí ó lè máa gbúròó bí ẹ ti ń ṣe, pé ẹ̀yin dúró ṣinṣin nínú Ẹ̀mí kan, ẹ̀yin jùmọ̀ jìjàkadì nítorí ìgbàgbọ́ ìyìnrere, pẹ̀lú ọkàn kan.
ki ma digero daten fulen keret kiristi, na nyori. no bou mato komri kaka'a mi mani ri, nuwa kimen kom tim kibi kwamer mor yuwa tangbe wucake wiin ki nero wiin, kwilki-kwilki ker fulen keret kwama.
28 Kí ẹ má sì jẹ́ ki àwọn ọ̀tá dẹ́rùbà yin ni ohunkóhun: èyí tí í ṣe àmì tí ó dájú pé a ó pa wọ́n run, ṣùgbọ́n Ọlọ́run tìkára rẹ̀ ni yóò gbà yin là.
ki nuware tai nubo wuro yilam nob kiye kime. wuro yirom cinen na wuroka ciko ce, kime fuloka kime ko-wuro kwama nin ne.
29 Nítorí tí a ti fún yin ni àǹfààní, kì í ṣe láti gba Kristi gbọ́ nìkan, ṣùgbọ́n láti jìyà nítorí rẹ̀ pẹ̀lú.
cin nekom yiber ker kiristi, kebo ka neka bilengke cinen ka-nge nuwa ka dotangen ker cer,
30 Ẹ sì máa ja ìjà kan náà, èyí ti ẹ̀yin ti ri, ti ẹ sì ti gbọ́ pé èmi n jà pẹ̀lú.
na dontang wo ka to mine neu, la can ka tuwe.

< Philippians 1 >