< Lamentations 3 >

1 Èmi ni ọkùnrin tí ó rí ìpọ́njú pẹ̀lú ọ̀pá ìbínú rẹ.
Mene ɔbarima a mahu amane wɔ nʼabufuw abaa ano.
2 Ó ti lé mi jáde ó sì mú mi rìn nínú òkùnkùn ju ti ìmọ́lẹ̀.
Wapam me afi ne ho ama manantew sum mu na ɛnyɛ hann mu;
3 Nítòótọ́, ó ti yí ọwọ́ rẹ̀ padà sí mi síwájú àti síwájú sí i ní gbogbo ọjọ́.
Ampa ara wama nsa so atia me mpɛn bebree, da mu nyinaa.
4 Ó jẹ́ kí àwọ̀ mi àti ẹran-ara mi gbó ó sì tún ṣẹ́ egungun mi.
Wama me were ne me nam anyin Na wabubu me nnompe.
5 Ó ti fi mí sí ìgbèkùn, ó sì ti yí mi ká pẹ̀lú ìkorò àti làálàá.
Waka me ahyɛ mu, na watua me ano ɔde nweenwen ne ahokyere atwa me ho ahyia.
6 Ó mú mi gbé nínú òkùnkùn, bí ti àwọn tó ti kú fún ìgbà pípẹ́.
Wama matena sum mu sɛ wɔn a wɔawuwu dedaw no.
7 Ó ti tì mí mọ́ ilé, nítorí náà n kò le è sálọ; ó ti fi ẹ̀wọ̀n mú mi mọ́lẹ̀.
Wato ɔfasu atwa me ho ahyia enti mintumi nguan; wagu me nkɔnsɔnkɔnsɔn ama matɔ beraw.
8 Pàápàá nígbà tí mo ké fún ìrànlọ́wọ́, ó kọ àdúrà mi.
Mpo sɛ mefrɛ anaasɛ mebɔ mpae srɛ mmoa a osiw me mpaebɔ ano.
9 Ó fi ògiri òkúta dí ọ̀nà mi; ó sì mú ọ̀nà mi wọ́.
Ɔde abotan asiw me kwan; wama mʼakwan ayɛ kɔntɔnkye.
10 Bí i beari tí ó dùbúlẹ̀, bí i kìnnìún tí ó sá pamọ́.
Te sɛ sisi a ɔda hɔ retwɛn, te sɛ gyata a watɛw,
11 Ó wọ́ mi kúrò ní ọ̀nà, ó tẹ̀ mí mọ́lẹ̀ ó fi mi sílẹ̀ láìsí ìrànlọ́wọ́.
ɔtwee me fii ɔkwan no mu bebaree me na ogyaw me a minni mmoa biara.
12 Ó fa ọfà rẹ̀ yọ ó sì fi mí ṣe ohun ìtafàsí.
Okuntun ne ta mu na ɔde ne bɛmma kyerɛɛ me so.
13 Ó fa ọkàn mí ya pẹ̀lú ọfà nínú àkọ̀ rẹ̀.
Ɔde bɛmma a efi ne kotoku mu hwirew me koma mu.
14 Mo di ẹni yẹ̀yẹ́ láàrín àwọn ènìyàn mi; wọn yẹ̀yẹ́ mi pẹ̀lú orin ní gbogbo ọjọ́.
Meyɛɛ akyiwade maa me nkurɔfo nyinaa; wɔto akutia nnwom de di me ho fɛw da mu nyinaa.
15 Ó ti kún mi pẹ̀lú ewé kíkorò àti ìdààmú bí omi.
Ɔde nhaban nweenwen ahyɛ me ma. Wama me bɔnwoma anom.
16 Ó ti fi òkúta kán eyín mi; ó ti tẹ̀ mí mọ́lẹ̀ nínú eruku.
Ɔde mmosea abubu me se; na watiatia me so wɔ mfutuma mu.
17 Mo ti jìnnà sí àlàáfíà; mo ti gbàgbé ohun tí àṣeyege ń ṣe.
Wɔama asomdwoe abɔ me; na me werɛ afi yiyedi.
18 Nítorí náà mo wí pé, “Ògo mi ti lọ àti ìrètí mi nínú Olúwa.”
Enti mise, “Mʼanuonyam asa, nea mede mʼani too so Awurade mu no nyinaa.”
19 Mo ṣe ìrántí ìpọ́njú àti ìdààmú mi, ìkorò àti ìbànújẹ́.
Mekae mʼamanehunu wɔ mʼakyinkyinakyinkyin mu, nweenwen ne bɔnwoma mu.
20 Mo ṣèrántí wọn, ọkàn mi sì gbọgbẹ́ nínú mi.
Mekae yiye, na me kra abotow wɔ me mu.
21 Síbẹ̀, èyí ni mo ní ní ọkàn àti nítorí náà ní mo nírètí.
Nanso midwen eyi ho; saa nti mewɔ anidaso.
22 Nítorí ìfẹ́ Olúwa tí ó lágbára ni àwa kò fi ṣègbé, nítorí ti àánú rẹ kì í kùnà.
Awurade dɔ kɛse nti yɛnsɛee ɛ. Nʼayamhyehye nni huammɔ.
23 Wọ́n jẹ́ ọ̀tún ní àárọ̀; títóbi ni òdodo rẹ̀.
Ɛyɛ foforo anɔpa biara; wo nokwaredi yɛ kɛse.
24 Mo wí fún ara mi, ìpín mi ni Olúwa; nítorí náà èmi yóò dúró dè ọ́.
Meka kyerɛ me ho se, “Awurade yɛ me kyɛfa, enti mɛtwɛn no.”
25 Dídára ni Olúwa fún àwọn tí ó ní ìrètí nínú rẹ̀, sí àwọn tí ó ń wá a.
Awurade ye ma wɔn a wɔn anidaso wɔ ne mu, onipa a ɔhwehwɛ no no;
26 Ó dára kí a ní sùúrù fún ìgbàlà Olúwa.
Eye sɛ wɔyɛ komm de twɛn Awurade nkwagye.
27 Ó dára fún ènìyàn láti gbé àjàgà nígbà tí ó wà ní èwe.
Eye ma ɔbarima sɛ ɔsoa konnua no wɔ ne mmerantebere mu.
28 Jẹ́ kí ó jókòó ní ìdákẹ́ jẹ́ẹ́, nítorí Olúwa ti fi fún un.
Ma ɔntena ase komm, efisɛ Awurade de ato ne so.
29 Jẹ́ kí ó bo ojú rẹ̀ sínú eruku— ìrètí sì lè wà.
Ma ɔmfa nʼanim nsie wɔ mfutuma mu, ebia anidaso wɔ hɔ.
30 Jẹ́ kí ó fi ẹ̀rẹ̀kẹ́ fún àwọn tí yóò gbá a, sì jẹ́ kí ó wà ní ìdójútì.
Ma ɔmfa nʼafono mma nea ɔpɛɛ sɛ ɔbɔ no no na ɔnhyɛ no aniwu.
31 Ènìyàn kò di ìtanù lọ́dọ̀ Olúwa títí láé.
Na Awurade ntow onipa biara nkyene koraa.
32 Lóòtítọ́ ó mú ìbànújẹ́ wá, yóò fi àánú hàn, nítorí títóbi ni ìfẹ́ rẹ̀.
Ɛwɔ mu, ɔde awerɛhow ba de, nanso obenya ayamhyehye. Ne dɔ kɛse no to rentwa da.
33 Nítorí kò mọ̀ ọ́n mọ̀ mú ìpọ́njú wá tàbí ìrora wá fún ọmọ ènìyàn.
Ofi amemenemfe mu de amanehunu anaa awerɛhow brɛ nnipa mma.
34 Láti tẹ mọ́lẹ̀ lábẹ́ ẹsẹ̀ gbogbo àwọn ẹlẹ́wọ̀n ní ilẹ̀ náà.
Sɛ wɔde wɔn nan dwerɛw nneduafo a wɔwɔ asase no so a,
35 Láti ṣẹ́ ọmọ ènìyàn fún ẹ̀tọ́ rẹ̀ níwájú Ọ̀gá-ògo jùlọ,
sɛ wotiatia obi ahofadi so wɔ Ɔsorosoroni no anim a,
36 láti yí ìdájọ́ ènìyàn padà, ǹjẹ́ Olúwa kò rí ohun bẹ́ẹ̀.
anaa sɛ wobu obi ntɛnkyew a, Awurade renhu saa nneɛma yi ana?
37 Ta ni yóò sọ̀rọ̀ tí yóò rí bẹ́ẹ̀ tí Olúwa kò bá fi àṣẹ sí i.
Hena na obetumi aka na wama aba mu wɔ bere a ɛnyɛ Awurade na ɔhyɛe?
38 Ǹjẹ́ kì í ṣe láti ẹnu Ọ̀gá-ògo jùlọ ni rere àti búburú tí ń wá?
Ɛnyɛ Ɔsorosoroni no anom na mmusu ne nnepa fi ana?
39 Kí ló dé tí ẹ̀dá alààyè ṣe ń kùn nígbà tí ó bá ń jìyà ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀?
Adɛn nti na ɛsɛ sɛ ɔteasefo nwiinwii bere a wɔatwe nʼaso wɔ ne bɔne ho?
40 Ẹ jẹ́ kí a yẹ ọ̀nà wa, kí a sì dán an wò, kí a sì tọ Olúwa lọ.
Momma yɛnhwehwɛ yɛn akwan mu na yɛnsɔ nhwɛ, na yɛnsan nkɔ Awurade nkyɛn.
41 Ẹ jẹ́ kí a gbé ọkàn àti ọwọ́ wa sókè sí Ọlọ́run ní ọ̀run, kí a wí pé,
Momma yɛmma yɛn koma ne yɛn nsa so, nkyerɛ Onyankopɔn wɔ ɔsoro, na yɛnka se:
42 “Àwa ti ṣẹ̀ a sì ti ṣọ̀tẹ̀ ìwọ kò sì fi ẹ̀ṣẹ̀ wa jì wá.
“Yɛayɛ bɔne, na yɛatew atua na wamfa ankyɛ.
43 “Ìwọ fi ìbínú bo ara rẹ ìwọ sì ń lépa wa; ìwọ ń parun láìsí àánú.
“Wode abufuw akata wo ho ataa yɛn; na woakunkum a woannya ahummɔbɔ.
44 Ìwọ ti fi àwọsánmọ̀ bo ara rẹ pé kí àdúrà wa má ba à dé ọ̀dọ̀ rẹ.
Wode wo ho asie omununkum mu nti mpaebɔ biara nnu wo nkyɛn.
45 Ó ti sọ wá di èérí àti ààtàn láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo.
Woayɛ yɛn atantanne ne nwura wɔ amanaman no mu.
46 “Gbogbo àwọn ọ̀tá wa ti la ẹnu wọn gbòòrò sí wa.
“Yɛn atamfo nyinaa abaa wɔn anom tɛtrɛɛ de tia yɛn.
47 Àwa ti jìyà àti ìparun, nínú ìbẹ̀rù àti ewu.”
Yɛabrɛ ne ahunahuna ne akukuruhwease, mmubui ne ɔsɛe.”
48 Omijé ń sàn ní ojú mi bí odò nítorí a pa àwọn ènìyàn mi run.
Me nusu sen sɛ asuten efisɛ wɔasɛe me nkurɔfo.
49 Ojú mi kò dá fún omijé, láì sinmi,
Me nusu bɛsen ara, na ɛrennyae,
50 títí ìgbà tí Olúwa yóò síjú wolẹ̀ láti òkè ọ̀run tí yóò sì rí i.
kosi sɛ Awurade bɛhwɛ afi ɔsoro, na wahu.
51 Ohun tí mo rí mú ìbẹ̀rù wá ọkàn mi nítorí gbogbo àwọn obìnrin ìlú mi.
Nea mihu no ma me kra werɛ how, me kuropɔn no mu mmea nyinaa nti.
52 Àwọn tí ó jẹ́ ọ̀tá mi láìnídìí dẹ mí bí ẹyẹ.
Mʼatamfo a menyɛɛ wɔn hwee pampam me sɛ anomaa.
53 Wọ́n gbìyànjú láti mú òpin dé bá ayé mi nínú ihò wọ́n sì ju òkúta lù mí.
Wɔpɛɛ sɛ wotwa me nkwa so na wosiw me abo wɔ amoa mu;
54 Orí mi kún fún omi, mo sì rò pé ìgbẹ̀yìn dé.
nsu bu faa me ti so, na ɛyɛɛ me sɛnea wɔrewie me.
55 Mo pe orúkọ rẹ, Olúwa, láti ọ̀gbun ìsàlẹ̀ ihò.
Mebɔɔ wo din, Awurade fii amoa no ase tɔnn.
56 Ìwọ gbọ́ ẹ̀bẹ̀ mi, “Má ṣe di etí rẹ sí igbe ẹ̀bẹ̀ mi fún ìtura.”
Wotee me sufrɛ: “Nsiw wʼaso wɔ me gye sufrɛ ho.”
57 O wá tòsí nígbà tí mo ké pè ọ́, o sì wí pé, “Má ṣe bẹ̀rù.”
Wutwiw bɛn me bere a mefrɛɛ wo no, na wokae se, “Nsuro.”
58 Olúwa, ìwọ gba ẹjọ́ mi rò, o ra ẹ̀mí mi padà.
Wo Awurade, wudii mʼasɛm maa me; na wugyee me nkwa.
59 O ti rí i, Olúwa, búburú tí a ṣe sí mi. Gba ẹjọ́ mi ró!
Woahu bɔne a wɔayɛ me, Awurade. Di mʼasɛm ma me!
60 Ìwọ ti rí ọ̀gbun ẹ̀san wọn, gbogbo ìmọ̀ wọn sí mi.
Woahu wɔn aweretɔ no mu den, wɔn pɔw a wɔbɔ tia me no nyinaa.
61 Olúwa ìwọ ti gbọ́ ẹ̀gàn wọn àti ìmọ̀ búburú wọn sí mi,
Awurade, woate wɔn ntwirii, wɔn pɔw a wɔbɔ tia me no nyinaa,
62 ohun tí àwọn ọ̀tá mi ń sọ sí mi ní gbogbo ọjọ́.
nea mʼatamfo ka no asomsɛm na wɔka no brɛoo de tia me da mu nyinaa.
63 Wò wọ́n! Ní jíjòkòó tàbí ní dídìde, wọ́n ń ṣẹlẹ́yà mi nínú orin wọn.
Hwɛ wɔn! Sɛ wogyinagyina hɔ anaasɛ wɔtete hɔ, wɔto akutia nnwom de di me ho fɛw.
64 Olúwa san wọ́n lẹ́san ohun tí ó tọ́ sí wọn fún ohun tí ọwọ́ wọn ti ṣe.
Fa nea ɛfata tua wɔn so ka, Awurade, nea wɔn nsa ayɛ nti.
65 Fi ìbòjú bò wọ́n ní ọkàn, kí o sì fi wọ́n ré.
Pirim wɔn koma, na ma wo nnome mmra wɔn so.
66 Ni wọ́n lára kí o sì pa wọ́n run pẹ̀lú ìbínú, lábẹ́ ọ̀run Olúwa.
Fa abufuw taa wɔn, na sɛe wɔn fi Awurade ɔsorosoro ase.

< Lamentations 3 >