< Job 31 >

1 “Mo ti bá ojú mi dá májẹ̀mú, èmi yó ha ṣe tẹjúmọ́ wúńdíá?
Am făcut un legământ cu ochii mei; de ce atunci să mă gândesc la o tânără?
2 Nítorí pé kí ni ìpín Ọlọ́run láti ọ̀run wá? Tàbí kí ni ogún Olódùmarè láti òkè ọ̀run wá.
Căci ce este partea de la Dumnezeu de sus și ce moștenire de la cel Atotputernic din înalt?
3 Kò ṣe pé àwọn ènìyàn búburú ni ìparun wà fún, àti àjàkálẹ̀-ààrùn fún àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀?
Nu este nimicire pentru cel stricat? Și o pedeapsă neobișnuită lucrătorilor nelegiuirii?
4 Òun kò ha ri ipa ọ̀nà mi, òun kò ha sì ka gbogbo ìṣísẹ̀ mi?
Nu vede el căile mele și nu numără toți pașii mei?
5 “Bí ó bá ṣe pé èmi bá fi àìṣòótọ́ rìn, tàbí tí ẹsẹ̀ mi sì yára sí ẹ̀tàn,
Dacă am umblat în deșertăciune, sau dacă piciorul meu s-a grăbit la înșelăciune,
6 (jẹ́ kí Ọlọ́run wọ́n mí nínú ìwọ̀n òdodo, kí Ọlọ́run le mọ ìdúró ṣinṣin mi.)
Să fiu cântărit într-o balanță dreaptă, ca Dumnezeu să îmi cunoască integritatea.
7 Bí ẹsẹ̀ mí bá yà kúrò lójú ọ̀nà, tí àyà mí sì tẹ̀lé ipa ojú mi, tàbí bí àbàwọ́n kan bá sì lẹ̀ mọ́ mi ní ọwọ́,
Dacă mi s-a abătut pasul de pe cale și inima mea mi-a urmat ochii și dacă vreo pată s-a lipit de mâinile mele,
8 ǹjẹ́ kí èmi kí ó gbìn kí ẹlòmíràn kí ó sì mújẹ, àní kí a fa irú-ọmọ mi tu.
Atunci să seamăn și să mănânce altul; da, să fie dezrădăcinați urmașii mei.
9 “Bí àyà mi bá di fífà sí ipasẹ̀ obìnrin kan, tàbí bí mo bá lọ í ba de ènìyàn ní ẹnu-ọ̀nà ilé aládùúgbò mi,
Dacă inima mea a fost înșelată de vreo femeie, sau dacă am pândit la ușa aproapelui meu,
10 kí àyà mi kí ó lọ ọlọ fún ẹlòmíràn, kí àwọn ẹlòmíràn kí ó tẹ̀ ara wọn ní ara rẹ̀.
Atunci să macine soția mea pentru altul și alții să se aplece peste ea.
11 Nítorí pé yóò jẹ́ ohun ìtìjú àní, ẹ̀ṣẹ̀ tí a ó ṣe onídàájọ́ rẹ̀.
Căci aceasta este o crimă odioasă; da, este o nelegiuire [c]e trebuie pedepsită de judecători.
12 Nítorí pé iná ní èyí tí ó jó dé ibi ìparun, tí ìbá sì fa gbòǹgbò ohun ìbísí mi gbogbo tu.
Pentru că este un foc ce mistuie până la nimicire și care ar dezrădăcina tot venitul meu.
13 “Tí mo bá sì ṣe àìka ọ̀ràn ìránṣẹ́kùnrin mi tàbí ìránṣẹ́bìnrin mi sí, nígbà tí wọ́n bá ń bá mi jà;
Dacă am disprețuit cauza servitorului meu sau a servitoarei mele, când s-au certat cu mine;
14 kí ni èmi ó ha ṣe nígbà tí Ọlọ́run bá dìde? Nígbà tí ó bá sì ṣe ìbẹ̀wò, ohùn kí ni èmi ó dá?
Ce voi face atunci când Dumnezeu se ridică? Și când cercetează, ce îi voi răspunde?
15 Ẹni tí ó dá mi ní inú kọ́ ni ó dá a? Ẹnìkan náà kí ó mọ wá ní inú ìyá wa?
Cel care m-a făcut pe mine în pântece, nu l-a făcut și pe el? Și nu unul ne-a format în pântece?
16 “Bí mo bá fa ọwọ́ sẹ́yìn fún ìfẹ́ inú tálákà, tàbí bí mo bá sì mú kí ojú opó rẹ̀wẹ̀sì,
Dacă am împiedicat pe săraci de la dorința lor, sau am făcut ochii văduvei să se sfârșească;
17 tàbí tí mo bá nìkan bu òkèlè mi jẹ, tí aláìní baba kò jẹ nínú rẹ̀;
Sau am mâncat bucata mea singur și cel fără tată nu a mâncat din ea;
18 nítorí pé láti ìgbà èwe mi wá ni a ti tọ́ ọ dàgbà pẹ̀lú mi bí ẹni pé baba, èmi sì ń ṣe ìtọ́jú opó láti inú ìyá mi wá:
(Căci din tinerețea mea el a fost crescut cu mine, precum cu un tată; și am îndrumat-o din pântecele mamei mele);
19 bí èmi bá rí olùpọ́njú láìní aṣọ, tàbí tálákà kan láìní ìbora;
Dacă am văzut pe cineva pierind din lipsă de haină, sau vreun sărac fără învelitoare,
20 bí ọkàn rẹ̀ kò bá súre fún mi, tàbí bí ara rẹ̀ kò sì gbóná nípasẹ̀ irun àgùntàn mi;
Dacă coapsele lui nu m-au binecuvântat și dacă el nu a fost încălzit cu lâna oilor mele,
21 bí mo bá sì gbé ọwọ́ mi sókè sí aláìní baba, nítorí pé mo rí ìrànlọ́wọ́ mi ní ẹnu ibodè,
Dacă mi-am ridicat mâna împotriva celui fără tată, când am văzut ajutorul meu în poartă,
22 ǹjẹ́, ní apá mi kí o wọ́n kúrò ní ihò èjìká rẹ̀, kí apá mi kí ó sì ṣẹ́ láti egungun rẹ̀ wá.
Să îmi cadă brațul din umărul meu și brațul să îmi fie frânt din os.
23 Nítorí pé ìparun láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá ni ẹ̀rù ńlá fún mi, àti nítorí ọláńlá rẹ̀ èmi kò le è dúró.
Căci nimicirea de la Dumnezeu mi-a fost teroare și din cauza înălțimii lui nu am putut îndura.
24 “Bí ó bá ṣe pé mo fi wúrà ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé mi, tàbí tí mo bá wí fún fàdákà dídára pé, ‘Ìwọ ni ààbò mi,’
Dacă am făcut aurul speranța mea, sau am spus aurului pur: Tu ești încrederea mea;
25 bí mo bá yọ̀ nítorí ọrọ̀ mí pọ̀, àti nítorí ọwọ́ mi dara lọ́pọ̀lọ́pọ̀,
Dacă m-am bucurat că bogăția mea era mare și că mâna mea a obținut mult,
26 bí mo bá bojú wo oòrùn nígbà tí ń ràn, tàbí òṣùpá tí ń ràn nínú ìtànmọ́lẹ̀,
Dacă am privit soarele când acesta strălucea, sau luna umblând în strălucire,
27 bí a bá tàn ọkàn mi jẹ láti fi ẹnu mi kò ọwọ́ mi,
Și inima mea a fost în ascuns ademenită, sau gura mea mi-a sărutat mâna,
28 èyí pẹ̀lú ni ẹ̀ṣẹ̀ ti àwọn onídàájọ́ ní láti bẹ̀wò, nítorí pé èmí yóò jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Ọlọ́run tí ó wà lókè.
Și aceasta ar fi nelegiuire [ce trebuie] pedepsită de judecător; fiindcă aș fi negat pe Dumnezeu de sus.
29 “Bí ó bá ṣe pé mo yọ̀ sì ìparun ẹni tí ó kórìíra mi. Tàbí bí mo bá sì gbéraga sókè, nígbà tí ibi bá a.
Dacă m-am bucurat la nimicirea celui ce m-a urât, sau m-am înălțat când răul l-a găsit,
30 Bẹ́ẹ̀ èmi kò sì jẹ ki ẹnu mi ki ó ṣẹ̀ nípa fífẹ́ ègún sí ọkàn rẹ̀.
Nici nu am permis ca gura mea să păcătuiască prin a dori un blestem sufletului său.
31 Bí àwọn ènìyàn inú àgọ́ mi kò bá lè wí pé, ‘Ta ni kò ì tí ì jẹ ẹran rẹ̀ ní àjẹyó?’
Dacă bărbații cortului meu nu au spus: O, de am fi avut din carnea lui, nu putem fi săturați!
32 Àlejò kò wọ̀ ni ìgboro rí; èmí ṣí ìlẹ̀kùn mi sílẹ̀ fún èrò.
Străinul nu a rămas noaptea în stradă, ci am deschis ușile mele călătorului.
33 Bí mo bá bò ẹ̀ṣẹ̀ mi mọ́lẹ̀ bí Adamu ni pápá, ẹ̀bi mi pamọ́ ni àyà mi.
Dacă am acoperit fărădelegile mele precum Adam, prin ascunderea nelegiuirii mele în sânul meu;
34 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni mo ha bẹ̀rù bí? Tàbí ẹ̀gàn àwọn ìdílé ní ń bà mí ní ẹ̀rù? Tí mo fi pa ẹnu mọ́, tí èmí kò sì fi sọ̀rọ̀ jáde?
M-am temut de o mare mulțime, sau disprețul familiilor m-a îngrozit, încât să tac și să nu ies afară pe ușă?
35 (“Ìbá ṣe pé ẹnìkan le gbọ́ ti èmí! Kíyèsi i, àmì mi, kí Olódùmarè kí ó dá mi lóhùn, kí èmí kí ó sì rí ìwé náà tí olùfisùn mi ti kọ.
O, de m-ar asculta cineva! Iată, dorința mea este ca cel Atotputernic să îmi răspundă și potrivnicul meu să fi scris o carte.
36 Nítòótọ́ èmí ìbá gbé le èjìká mi, èmi ìbá sì dé bí adé mọ́ orí mi.
Cu siguranță aș lua-o pe umărul meu și mi-aș lega-o ca pe o coroană.
37 Èmi ìbá sì sọ iye ìṣísẹ̀ mi fún un, bí ọmọ-aládé ni èmi ìbá súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ̀.)
I-aș spune numărul pașilor mei; ca un prinț m-aș apropia de el.
38 “Bí ilẹ̀ mi bá sì ké rara lòdì sí mi tí a sì fi omijé kún gbogbo poro rẹ̀.
Dacă pământul meu strigă împotriva mea, sau dacă brazdele [lui] în același fel se plâng,
39 Bí mo bá jẹ èso oko mi láìsan owó tàbí tí mo sì mú ọkàn olúwa rẹ̀ fò lọ,
Dacă i-am mâncat roadele fără bani, sau am făcut pe proprietarii lui să își piardă viața,
40 kí ẹ̀gún òṣùṣú kí ó hù dípò alikama, àti èpò búburú dípò ọkà barle.” Ọ̀rọ̀ Jobu parí.
Să crească ciulini în loc de grâu și neghine în loc de orz. Cuvintele lui Iov s-au terminat.

< Job 31 >