< Jeremiah 21 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jeremiah wá nígbà tí ọba Sedekiah rán Paṣuri ọmọ Malkiah àti àlùfáà Sefaniah ọmọ Maaseiah sí i; wọ́n wí pé:
Yuda hina bagade, Sedegaia, da Ba: sie (Ma: legaia egefe) amola Sefanaia (Ma: iasia egefe) nama adole ba: musa: asunasi.
2 “Wádìí lọ́wọ́ Olúwa fún wa nítorí Nebukadnessari ọba Babeli ń kọlù wá. Bóyá Olúwa yóò ṣe ìyanu fún wa gẹ́gẹ́ bí ti àtẹ̀yìnwá, kí ó sì yípadà kúrò lọ́dọ̀ wa.”
Ela da nama amane adole ba: i, “Ninia dima dafawane edegesa. Hina Gode da nini fidima: ne sia: ma. Bai Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese amola ea dadi gagui dunu da moilaiga doagala: lala. Amabela: ? Hina Gode da nini fidima: ne, degabo ba: su hou afae hamosea, Nebiuga: denese da hobeama: bela: ?”
3 Ṣùgbọ́n Jeremiah dáhùn wí pé, “Sọ fún Sedekiah,
Amalalu, Hina Gode da nama sia: i, amola na da nama asunasi dunu amoma alofele sia: i,
4 ‘Èyí ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli wí, Èmi fẹ́ kọjú idà tí ó wà lọ́wọ́ yín sí yín, èyí tí ẹ̀ ń lò láti bá ọba àti àwọn ará Babeli tí wọ́n wà lẹ́yìn odi jà, Èmi yóò sì kó wọn jọ sínú ìlú yìí.
“Hina Gode, Isala: ili ilia Gode, da Sedegaiama amane sia: sa, ‘Sedegaia! Dia dadi gagui wa: i amo da Ba: bilone hina amola ea dadi gagui dunu ilima gegenana, amo Na da hasalimu. Na da dilia gegesu liligi huluane moilai bai bagade dogoa gilisili lelegela heda: mu.
5 Èmi gan an yóò sì bá yín jà pẹ̀lú ohun ìjà olóró nínú ìbínú àti ìrunú líle.
Na da Na gasaga amola Na ougi bagadedafa amoga dima gegemu.
6 Èmi yóò sì lu gbogbo ìlú yìí, ènìyàn àti ẹranko, gbogbo wọn ni àjàkálẹ̀-ààrùn yóò kọlù tí wọn yóò sì kú.
Dunu huluanedafa amo moilai ganodini esala, amo Na da medole legemu. Dunu amola ohe fi defele da oloi wadela: idafa amoga bogogia: mu.
7 Olúwa sọ pé lẹ́yìn èyí, èmi yóò fi Sedekiah ọba Juda, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àti àwọn ènìyàn, àti àwọn tí ó kù ní ìlú yìí lọ́wọ́ àjàkálẹ̀-ààrùn àti lọ́wọ́ idà, àti lọ́wọ́ ìyàn; èmi yóò fi wọ́n lé Nebukadnessari ọba Babeli lọ́wọ́, àti lé ọwọ́ àwọn ọ̀tá wọn, àti lé ọwọ́ àwọn tí ń lépa ẹ̀mí wọn, òun yóò sì fi ojú idà pa wọ́n, kì yóò sì dá wọn sí, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò ní ìyọ́nú tàbí ṣàánú wọn.’
Be di, amola dia eagene ouligisu dunu, amola nowa da gegesu amoga hame bogoi esalea, amo Na da logo doasimuba: le, hina bagade Nebiuga: denese amola dilia ha lai dunu (ilia dili medole legemu hanai) da dili gagulaligimu. Nebiuga: denese da dili medole legemu. E da dili dunu afae amoma hamedafa asigimu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.’”
8 “Síwájú sí i, sọ fún àwọn ènìyàn, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó sọ: Wò ó, Èmi ń fi ọ̀nà ìyè àti ikú hàn yín.
Amalalu, Hina Gode da na da dunu huluane ilima amane sia: ma: ne sia: i, “Nabima! Na, Hina Gode, da dili afae ilegema: ne, logo aduna dilima olelesa. Logo afae da esalusu amoga doaga: sa. Eno da bogosu amoga doaga: sa.
9 Ẹnikẹ́ni tí ó bá dúró sí ìlú yìí yóò ti ipa idà, ìyàn tàbí àjàkálẹ̀-ààrùn kú. Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá jáde tí ó sì jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún àwọn Babeli tí ó ń lépa yín yóò sì yè. Òun yóò sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀.
Nowa da Yelusaleme mae yolesili amo ganodini esalea, da ha: ga o olobeba: le bogomu. Be nowa da gadili Ba: bilone dunu (amo da moilaiga doagala: lala) amo gagulaligimusa: ahoasea, da bogosu hame ba: mu. E da esalumu fawane.
10 Mo ti pinnu láti jẹ ìlú yìí ní yà, ni Olúwa wí. A ó sì gbé e fún ọba Babeli, yóò sì run ún pẹ̀lú iná.’
Na da amo moilai bai bagade wadela: musa: ilegeidafa. Na da amo moilai bai bagade, Ba: bilone hina bagadema imunu. Amola e da amo laluga ulagili, osobo amola nasubu fawane dialebe ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
11 “Ẹ̀wẹ̀, wí fún ìdílé ọba Juda pé, ‘Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
Hina Gode da amo sia: Yuda hina bagade fi (Da: ibidi egaga fi) ilima sia: ma: ne sia: i, “Nabima! Na, Hina Gode da amane sia: sa! Moloidafa hou eso huluane hamoma: ne, ouligima! Ogogosu hamosu dunu ilia logo hedofama, amola dunu ilima ilia da ogogosa, amo gaga: ma! Amane hame hamoi ganiaba, Na ougi da lalu ha: ba: domu hamedei agoai nenana: loba.
12 Ilé Dafidi èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa sọ: “‘Ṣe ìdájọ́ tí ó tọ́ ní àràárọ̀; yọ ọ́ kúrò lọ́wọ́ ẹni tí ó ń ni í lára ẹni tí a ti jà lólè bí bẹ́ẹ̀ kọ́ ìbínú mi yóò jáde síta, yóò sì jó bí iná. Nítorí ibi tí a ti ṣe yóò sì jó láìsí ẹni tí yóò pa á.
13 Mo kẹ̀yìn sí ọ, Jerusalẹmu, ìwọ tí o gbé lórí àfonífojì lórí òkúta tí ó tẹ́jú, ni Olúwa wí. Ìwọ tí o ti wí pé, “Ta ni ó le dojúkọ wá? Ta ni yóò wọ inú ibùgbé wa?”
Dili! Yelusaleme fi! Dilia da igi bagade amo umi da: iya gado heda: le lelebe defele, hahawane fago da: iya gado esalebe ba: sa. Be Na da dilima gegemu. Dunu eno da dilima doagala: le, dilia gagoi amo fili, moilai bai bagade ganodini golili misunu da hamedei, dilisu hidale sia: sa.
14 Èmi yóò jẹ ọ ní ìyà gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ ni Olúwa wí. Èmi yóò mú kí iná jó ilé rẹ̀; yóò si jó gbogbo ohun tí ó wà ní àyíká rẹ.’”
Be dilia wadela: i hou hamobeba: le, Na da dilima se imunu. Na da dilia hina bagade diasu laluga ulagimu, amola amo lalu da liligi huluane amo sisiga: le dialebe, amo nene dagomu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”

< Jeremiah 21 >