< Isaiah 47 >

1 “Sọ̀kalẹ̀, jókòó nínú eruku, wúńdíá ọmọbìnrin Babeli; jókòó ní ilẹ̀ láìsí ìtẹ́, ọmọbìnrin àwọn ará Babeli. A kì yóò pè ọ́ ní aláìlókun àti ẹlẹgẹ́ mọ́.
“Atĩrĩrĩ, harũrũka ũikare thĩ rũkũngũ-inĩ, wee Mũirĩtu Gathirange wa Babuloni; ikara thĩ ũtaikarĩire gĩtĩ kĩa ũnene, wee Mwarĩ wa andũ a Babuloni. Ndũgacooka gũtuĩka mũndũ wa kũmenyererwo, kana mũndũ mũnyoroku ũtarĩ ũndũ angĩĩkĩra.
2 Mú òkúta-ọlọ kí o sì lọ ìyẹ̀fun; mú ìbòjú rẹ kúrò. Ká aṣọ ẹsẹ̀ rẹ sókè, ká aṣọ itan, kí o sì la odò wọ̀n-ọn-nì kọjá.
Oya mahiga ma gĩthĩi, ũthĩe mũtu; eheria gĩtambaya gĩa kwĩhumbĩra ũthiũ. Heta nguo ciaku na ũguũrie magũrũ maku, ũtoboke maaĩ-inĩ ũringe tũrũũĩ.
3 Ìhòhò rẹ ni a ó sí síta àti ìtìjú rẹ ni a ó ṣí sílẹ̀. Èmi yóò sì gba ẹ̀san, Èmi kì yóò sì dá ẹnìkan sí.”
Nĩũkarutwo nguo ũtigwo njaga, ũikare ũconorithĩtio. Nĩngerĩhĩria, na gũtirĩ mũndũ ngaiguĩra tha.”
4 Olùràpadà wa Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀ òun ni Ẹni Mímọ́ Israẹli.
Mũkũũri witũ, Jehova Mwene-Hinya-Wothe nĩrĩo Rĩĩtwa rĩake, nĩwe Ũrĩa Mũtheru wa Isiraeli.
5 “Jókòó ní ìdákẹ́ jẹ́ẹ́, lọ sínú òkùnkùn, ọmọbìnrin àwọn ará Babeli; a kì yóò pè ọ́ ní ọbabìnrin àwọn ilẹ̀ ọba mọ́.
“Wee Mwarĩ wa andũ a Babuloni, ikara thĩ ũkirĩte ki, ũthiĩ ũkinye nduma-inĩ; ndũgacooka gwĩtwo mũthamaki-mũndũ-wa-nja wa gwatha mothamaki.
6 Inú bí mi sí àwọn ènìyàn mi tí mo sì ba ogún mi jẹ́, mo fi wọ́n lé ọ lọ́wọ́, Ìwọ kò sì síjú àánú wò wọ́n. Lórí àwọn arúgbó pẹ̀lú ní o gbé àjàgà tí ó wúwo lé.
Nĩkũrakara ndaarakarĩĩtio nĩ andũ akwa, na ngĩtũma igai rĩakwa rĩthaahe; ngĩmaneana moko-inĩ maku, nawe ũkĩaga kũmaiguĩra tha. O na andũ arĩa akũrũ ũkĩmaigĩrĩra icooki iritũ mũno.
7 Ìwọ wí pé, ‘Èmi yóò tẹ̀síwájú títí láé— ọbabìnrin ayérayé!’ Ṣùgbọ́n ìwọ kò kíyèsi nǹkan wọ̀nyí tàbí kí o ronú nípa ohun tí ó lè ṣẹlẹ̀.
Nawe ũkiuga atĩrĩ, ‘Ngũtũũra ndĩ mũthamaki-mũndũ-wa-nja nginya tene!’ No wee ndũigana gũcũũrania maũndũ maya, o na kana wĩciirie ũrĩa ũhoro wamo wa kũrigĩrĩria ũgaikara.
8 “Nísinsin yìí, tẹ́tí sílẹ̀, ìwọ oníwọ̀ra ẹ̀dá tí o kẹ̀tẹ̀ǹfẹ̀ nínú ààbò rẹ tí o sì ń sọ fún ara rẹ pé, ‘Èmi ni, kò sì ṣí ẹlòmíràn lẹ́yìn mi. Èmi kì yóò di opó tàbí kí n pàdánù àwọn ọmọ.’
“Na rĩrĩ, ta thikĩrĩria, wee wendete ikeno, na ũikaraga ũtarĩ ũgwati ũngĩĩtigĩra, na ũkeĩraga atĩrĩ, ‘Niĩ no niĩ, na gũtirĩ ũngĩ tiga niĩ. Ndirĩ hĩndĩ ngaatuĩka mũtumia wa ndigwa, kana menye ũhoro wa gũkuĩrwo nĩ ciana.’
9 Méjèèjì yìí ni yóò wá sórí rẹ láìpẹ́ jọjọ, ní ọjọ́ kan náà: pípàdánù ọmọ àti dídi opó. Wọn yóò wá sórí rẹ ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́, pẹ̀lúpẹ̀lú àwọn ìṣe oṣó rẹ àti àwọn èpè rẹ tí ko lágbára.
Maũndũ macio meerĩ nĩmagagũkorerera o rĩmwe, mũthenya o ro ũmwe: nĩũgakuĩrwo nĩ ciana, na ũtuĩke mũtumia wa ndigwa. Maũndũ macio magaagũkorerera na ũiyũru biũ, o na gũtuĩka ũrĩ na ũrogi mũingĩ, na ũgo waku ũkaingĩha mũno.
10 Ìwọ ti ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú ìwà ìkà rẹ ó sì ti wí pé, ‘Kò sí ẹni tí ó rí mi?’ Ọgbọ́n àti òye rẹ ti ṣì ọ́ lọ́nà nígbà tí o wí fún ara rẹ pé, ‘Èmi ni, kò sí ẹlòmíràn lẹ́yìn mi.’
Ũtũire wĩhokete waganu waku, ũkoiga atĩrĩ, ‘Gũtirĩ mũndũ ũnyonaga.’ Ũũgĩ na ũmenyo waku nĩikũhĩtithagia rĩrĩa ũkwĩĩra atĩrĩ, ‘Niĩ no niĩ, na gũtirĩ ũngĩ tiga niĩ.’
11 Ìparun yóò dé bá ọ bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kì yóò mọ ọ̀nà láti ré e kúrò. Àjálù kan yóò ṣubú lù ọ́ tí o kì yóò le è fi ètùtù ré kúrò; òfò kan tí o kò le faradà ni yóò wá lójijì sí oríì rẹ.
Nĩ ũndũ ũcio mwanangĩko nĩũgagũkora, na ndũkaamenya ũrĩa ũngĩũũrĩra. Nĩũgakorererwo nĩ mũtino ũrĩa ũtangĩhota gwĩkũũra kuuma kũrĩ guo; ningĩ nĩũgakorererwo o ro rĩmwe nĩ ihooru rĩa maũndũ ũterĩgĩrĩire.
12 “Tẹ̀síwájú nígbà náà, pẹ̀lú àfọ̀ṣẹ rẹ àti pẹ̀lú ìwà oṣó rẹ gbogbo, tí o ti ń ṣiṣẹ́ fún láti ìgbà èwe rẹ wá. Bóyá o le è ṣàṣeyọrí, bóyá o le è dá rúgúdù sílẹ̀.
“Wee thiĩ na mbere na ciama ciaku cia ũgo, na ũrogi waku mũingĩ ũrĩa ũtũire wĩkaga kuuma ũrĩ mũnini. No gũkorwo hihi nĩũkona kĩguni kĩa mo, kana hihi ũtũme kũgĩe na itua-nda inene.
13 Gbogbo ìmọ̀ràn tí o ti gbà ni ó ti sọ ọ́ di akúrẹtẹ̀! Jẹ́ kí àwọn awòràwọ̀ rẹ bọ́ síwájú, àwọn awòràwọ̀ tí wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀ láti oṣù dé oṣù, jẹ́ kí wọ́n gbà ọ́ lọ́wọ́ ohun tí ó ń bọ̀ wá bá ọ.
Irĩra iria ciothe ũheetwo no gũkũnogia ikũnogetie! Ago aku arĩa maroraga igũrũ matu-inĩ nĩmeyumĩrie, acio matuĩragia njata na makaratha mohoro o mweri, o mweri-rĩ, nĩmagĩkũhonokie kuuma kũrĩ maũndũ marĩa megũgũkorerera.
14 Lóòótọ́ wọ́n dàbí ìṣẹ́pẹ́ igi; iná ni yóò jó wọn dànù. Wọn kò kúkú lè gba ara wọn là lọ́wọ́ agbára iná náà. Kò sí èédú láti mú ara ẹnikẹ́ni gbóná níhìn-ín kò sí iná tí ènìyàn le jókòó tì.
Ti-itherũ, andũ acio mahaana ta itira iria itigĩtwo mũgũnda; nĩgũcinwo magaacinwo nĩ mwaki mathire. Matikahota kwĩhonokia kuuma kũrĩ hinya wa rũrĩrĩmbĩ rwa mwaki, nĩgũkorwo hatigaakorwo makara mangĩotwo mwaki; hatirĩ mwaki haha ũngĩotwo.
15 Gbogbo ohun tí wọ́n lè ṣe fún ọ nìyìí gbogbo èyí ní o tí ṣíṣẹ́ pẹ̀lú u rẹ̀ tí o sì ti ń rù kiri láti ìgbà èwe. Ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn ń lọ nínú àṣìṣe rẹ̀; kò sí ẹyọ ẹnìkan tí ó lè gbà ọ́.
Ũguo noguo mangĩgwĩkĩra, aya mwanarutithania wĩra na mũkonjorithia nao kuuma rĩrĩa warĩ mũnini. O mũndũ wao athiiaga o na mbere kũhĩtia; gũtigakorwo mũndũ o na ũmwe ũngĩgĩkũhonokia.

< Isaiah 47 >