< Isaiah 43 >

1 Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí, ohun tí Olúwa wí nìyìí, ẹni tí ó dá ọ, ìwọ Jakọbu, ẹni tí ó mọ ọ́, ìwọ Israẹli: “Má bẹ̀rù, nítorí Èmi ti dá ọ nídè; Èmi ti pè ọ́ ní orúkọ; tèmi ni ìwọ ṣe.
No rĩrĩ, wee Jakubu, Jehova ũrĩa wakũũmbire, o we ũcio watũmire ũgĩe ho, wee Isiraeli, ekuuga atĩrĩ: “Tiga gwĩtigĩra, nĩgũkorwo nĩ niĩ ngũkũũrĩte; Ngwĩtĩte na rĩĩtwa rĩaku; wee ũrĩ wakwa.
2 Nígbà tí ìwọ bá ń la omi kọjá, Èmi yóò wà pẹ̀lú rẹ; àti nígbà tí ìwọ bá ń la odò kọjá wọn kì yóò bò ọ́ mọ́lẹ̀. Nígbà tí ìwọ bá la iná kọjá, kò ní jó ọ; ahọ́n iná kò ní jó ọ lára.
Rĩrĩa ũkũgerera maaĩ-inĩ ũkĩhĩtũkĩra kuo-rĩ, ndĩrĩkoragwo hamwe nawe; o na rĩrĩa ũkũringa njũũĩ-rĩ, itigagũtwara. Rĩrĩa ũkũgerera mwaki-inĩ-rĩ, ndũgaagũcina; ndũkarĩrĩmbũkĩrwo nĩ rũrĩrĩmbĩ rwaguo.
3 Nítorí Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ, Ẹni Mímọ́ Israẹli Olùgbàlà rẹ; Èmi fi Ejibiti ṣe ìràpadà rẹ, Kuṣi àti Seba dípò rẹ.
Nĩgũkorwo nĩ niĩ Jehova, Ngai waku, o we Ũrĩa Mũtheru wa Isiraeli, Mũhonokia waku; nĩheanĩte bũrũri wa Misiri ũtuĩke kĩndũ gĩa gũgũkũũra, nakuo Kushi na Seba ngakũheana ithenya rĩaku.
4 Nítorí pé o ṣe iyebíye àti ọ̀wọ́n níwájú mi, àti nítorí pé mo fẹ́ràn rẹ, Èmi yóò fi ènìyàn rọ́pò fún ọ, àti ènìyàn dípò ẹ̀mí rẹ.
Tondũ wee ũrĩ wa goro mũno, na ũgatĩĩka maitho-inĩ makwa, na tondũ nĩngwendete-rĩ, nĩnganeana andũ nĩ ũndũ waku, na neane ndũrĩrĩ nĩ ũndũ wa muoyo waku.
5 Má bẹ̀rù nítorí èmi wà pẹ̀lú rẹ; Èmi yóò mú àwọn ọmọ rẹ láti ìlà-oòrùn wá èmi ó sì kó ọ jọ láti ìwọ̀-oòrùn.
Tiga gwĩtigĩra, nĩgũkorwo ndĩ hamwe nawe; nĩngakũrehere ciana ciaku kuuma mwena wa irathĩro, na ngũcookanĩrĩrie kuuma mwena wa ithũĩro.
6 Èmi yóò sọ fún àríwá pé, ‘Fi wọ́n sílẹ̀!’ Àti fún gúúsù, ‘Má ṣe dá wọn dúró.’ Mú àwọn ọmọkùnrin mi láti ọ̀nà jíjìn wá àti àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin mi láti ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé—
Nĩngeera mwena wa gathigathini atĩrĩ, ‘Marekererie!’ na njĩĩre mwena wa gũthini atĩrĩ, ‘Tiga kũmagirĩrĩria.’ Ariũ akwa marehei moime kũndũ kũraya, o nao airĩtu akwa marehei moime ituri-inĩ ciothe cia thĩ:
7 ẹnikẹ́ni tí a ń pe orúkọ mi mọ́, tí mo dá fún ògo mi, tí mo mọ̀ àti tí mo ṣe.”
arĩa othe metanĩtio na rĩĩtwa rĩakwa, o acio ndoombire nĩgeetha riiri wakwa wonekage, acio ndoombire, o acio wĩra wa moko makwa.”
8 Sin àwọn tí ó ní ojú ṣùgbọ́n tí wọ́n fọ́jú jáde, tí wọ́n ní etí ṣùgbọ́n tí wọn dití.
Tongoriai andũ arĩa marĩ na maitho, no nĩ atumumu, na andũ arĩa marĩ na matũ, no matiiguaga.
9 Gbogbo orílẹ̀-èdè kó ra wọn jọ àwọn ènìyàn sì kó ra wọn papọ̀. Ta ni nínú wọn tó sọ àsọtẹ́lẹ̀ yìí tí ó sì kéde fún wa àwọn nǹkan ti tẹ́lẹ̀? Jẹ́ kí wọ́n mú àwọn ẹlẹ́rìí wọn wọlé wá láti fihàn pé wọ́n tọ̀nà tó bẹ́ẹ̀ tí àwọn mìíràn yóò gbọ́, tí wọn yóò sọ pé, “Òtítọ́ ni.”
Andũ a ndũrĩrĩ ciothe nĩmonganĩte hamwe, nao andũ a mabũrũri makagomana. Nĩ mũndũ ũrĩkũ wao warathire ũhoro ũyũ, na agĩtwĩra maũndũ marĩa maarĩ ma tene? Nĩmarehe aira ao moonanie atĩ ũhoro ũcio wao warĩ wa ma, nĩguo andũ maũigua moige atĩrĩ, “Ũhoro ũcio nĩ wa ma.”
10 “Ẹ̀yin ni ẹlẹ́rìí mi,” ni Olúwa wí, “Àti ìránṣẹ́ mi tí èmi ti yàn, tó bẹ́ẹ̀ tí ẹ̀yin yóò fi mọ̀ àti tí ẹ̀yin ó fi gbà mí gbọ́ tí yóò sì yé e yín pé èmi ni ẹni náà. Ṣáájú mi kò sí ọlọ́run tí a dá, tàbí a ó wa rí òmíràn lẹ́yìn mi.
“Inyuĩ nĩ inyuĩ aira akwa,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga. “O na nĩ inyuĩ ndungata ciakwa iria thuurĩte nĩgeetha mũmenye, na mũnjĩtĩkie, na mũmenye atĩ niĩ nĩ niĩ ũrĩa we. Mbere yakwa gũtirĩ ũngĩ wombĩtwo, na gũtikagĩa ũngĩ thuutha wakwa.
11 Èmi, àní Èmi, Èmi ni Olúwa, yàtọ̀ sí èmi, kò sí olùgbàlà mìíràn.
Niĩ-rĩ, o niĩ nĩ niĩ Jehova, na gũtirĩ mũhonokia ũngĩ tiga niĩ.
12 Èmi ti fihàn, mo gbàlà mo sì ti kéde Èmi, kì í sì í ṣe àwọn àjèjì òrìṣà láàrín yín. Ẹ̀yin ni ẹlẹ́rìí mi,” ni Olúwa wí, “Pé Èmi ni Ọlọ́run.
Niĩ-rĩ, nĩnguũranĩirie ũhoro, na ngahonokania, na ngoimbũra: Niĩ mwene, na ti ngai ngʼeni ĩrĩ thĩinĩ wanyu. Tondũ ũcio, inyuĩ nĩ inyuĩ aira akwa atĩ niĩ nĩ niĩ Mũrungu,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
13 Bẹ́ẹ̀ ni, àti láti ayérayé Èmi ni ẹni náà. Kò sí ẹnikẹ́ni tí ó lè gbà kúrò lọ́wọ́ mi. Nígbà tí mo bá ṣe nǹkan, ta ni ó lè yí i padà?”
“Ĩĩ, ti-itherũ, kuuma matukũ ma tene, niĩ nĩ niĩ ũrĩa we. Gũtirĩ mũndũ o na ũ ũngĩhota kũhonokia mũndũ kuuma guoko-inĩ gwakwa. Rĩrĩa ndeka ũndũ-rĩ, nũũ ũngĩhota kũũgarũra?”
14 Èyí ni ohun tí Olúwa wí, olùràpadà rẹ, Ẹni Mímọ́ ti Israẹli: “Nítorí rẹ Èmi yóò ránṣẹ́ sí Babeli láti mú wọn sọ̀kalẹ̀ wá gẹ́gẹ́ bí ìsáǹsá, gbogbo ará Babeli, nínú ọkọ̀ ojú omi nínú èyí tí wọ́n fi ń ṣe ìgbéraga.
Jehova, Mũhonokia wanyu, o Ũrĩa Mũtheru wa Isiraeli, ekuuga atĩrĩ, “Nĩngatũma mbũtũ ya ita yũkĩrĩre Babuloni nĩ ũndũ wanyu, na ndehe andũ othe a Babuloni marĩ mĩgwate, maikũrũkĩtio na marikabu iria makenagio nĩcio.
15 Èmi ni Olúwa, Ẹni Mímọ́ rẹ, Ẹlẹ́dàá Israẹli, ọba rẹ.”
Niĩ nĩ niĩ Jehova, Ũrĩa Mũtheru wanyu, Mũũmbi wa Isiraeli, na Mũthamaki wanyu.”
16 Èyí ni ohun tí Olúwa wí, Ẹni náà tí ó la ọ̀nà nínú Òkun, ipa ọ̀nà láàrín alagbalúgbú omi,
Ũũ nĩguo Jehova ekuuga, o ũcio watemire njĩra iria-inĩ, na agĩtema gacĩra kũndũ kũrĩa kwarĩ maaĩ marĩ hinya,
17 ẹni tí ó wọ́ àwọn kẹ̀kẹ́ àti ẹṣin jáde, àwọn jagunjagun àti ohun ìjà papọ̀, wọ́n sì sùn síbẹ̀, láìní lè dìde mọ́, wọ́n kú pirá bí òwú-fìtílà:
ũrĩa waguucĩrĩirie ngaari cia ita o na mbarathi, na mbũtũ cia ita, hamwe na anene a cio, nao magĩkoma hau na maticooke kwarahũka rĩngĩ, makĩhora biũ ta rũtambĩ rũhoretio.
18 “Gbàgbé àwọn ohun àtẹ̀yìnwá; má ṣe gbé nínú ohun àtijọ́.
“Tigai kũririkana maũndũ marĩa mahĩtũkĩte; o na tigai gwĩcũũrania maũndũ marĩa ma tene.
19 Wò ó, Èmi ń ṣe ohun tuntun! Nísinsin yìí, ó ti yọ sókè; àbí o kò rí i bí? Èmi ń ṣe ọ̀nà kan nínú aṣálẹ̀ àti odò nínú ilẹ̀ ṣíṣá.
Atĩrĩrĩ, nĩngwĩka ũndũ mwerũ! Rĩu no hĩndĩ ũraakunũka; kaĩ inyuĩ mũtaraũmenya? Ngwĩka atĩrĩ, nĩngũtema njĩra werũ-inĩ, nakuo rũngʼũrĩ-inĩ ndũme gũtherũke tũrũũĩ.
20 Àwọn ẹhànnà ẹranko bọ̀wọ̀ fún mi, àwọn ajáko àti àwọn òwìwí, nítorí pé mo pèsè omi nínú aṣálẹ̀ àti odò nínú ilẹ̀ sísá, láti fi ohun mímu fún àwọn ènìyàn mi, àyànfẹ́ mi,
Nyamũ cia gĩthaka, ta mbwe na ndundu, nĩciiheaga gĩtĩĩo, tondũ nĩ niĩ heanaga maaĩ werũ-inĩ o na rũngʼũrĩ-inĩ, ngatũma kũgĩe na tũrũũĩ twa kũnyuuagwo nĩ andũ akwa, andũ arĩa niĩ thuurĩte,
21 àwọn ènìyàn tí mo dá fún ara mi kí wọn kí ó lè kéde ìyìn mi.
andũ arĩa ndeyũmbĩire, nĩguo mahunjagie ũhoro wa ũgooci wakwa.
22 “Síbẹ̀síbẹ̀ ìwọ kò tí ì ké pè mí, ìwọ Jakọbu, àárẹ̀ kò tí ì mú ọ nítorí mi ìwọ Israẹli.
“No rĩrĩ, wee Jakubu ndũrĩ wangaĩra, nawe Isiraeli-rĩ, nĩkũnogio ũnogetio nĩ niĩ.
23 Ìwọ kò tí ì mú àgùntàn wá fún mi fún ẹbọ sísun, tàbí kí o bọ̀wọ̀ fún mi pẹ̀lú ẹbọ rẹ. Èmi kò tí ì wàhálà rẹ pẹ̀lú ọrẹ ìyẹ̀fun tàbí kí n dààmú rẹ pẹ̀lú ìbéèrè fún tùràrí.
Inyuĩ mũtindeheire ngʼondu cia maruta ma njino, kana mũkandĩĩithia na magongona manyu. Ndimũhatĩrĩirie na magongona ma mũtu, kana ngamũnogia na kũmwĩtia ũbumba.
24 Ìwọ kò tí ì ra kalamusi olóòórùn dídùn fún mi, tàbí kí o da ọ̀rá ẹbọ rẹ bò mí. Ṣùgbọ́n ẹ ti wàhálà mi pẹ̀lú ẹ̀ṣẹ̀ yín ẹ sì ti dààmú mi pẹ̀lú àìṣedéédéé yín.
Mũtirĩ mwangũrĩra ũbumba ũrĩa ũrĩ mũtararĩko mwega, o na kana mũkandutĩra maguta ma magongona manyu. No rĩrĩ, mehia manyu nĩmanditũhĩire na mũkaanogia na mawaganu manyu.
25 “Èmi, àní Èmi, Èmi ni ẹni tí ó wẹ àwọn àìṣedéédéé rẹ nù, nítorí èmi fún ara mi, tí n kò sì rántí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ mọ́.
“Niĩ, o niĩ mwene, nĩ niĩ tharagia mahĩtia maku, mathire biũ, nĩ ũndũ wakwa Niĩ mwene, na ngaaga kũririkana mehia manyu rĩngĩ.
26 Bojú wo ẹ̀yìn rẹ fún mi, jẹ́ kí a jọ ṣe àríyànjiyàn ọ̀rọ̀ náà papọ̀; ro ẹjọ́ láti fihàn pé o kò lẹ́sẹ̀ lọ́rùn.
Ta ndirikaniai maũndũ marĩa mahĩtũkĩte, na mũreke tũmaarĩrĩrie tũrĩ hamwe; ningĩ mũciire muonanie atĩ mũtiĩhĩtie.
27 Baba yín àkọ́kọ́ dẹ́ṣẹ̀; àwọn agbẹnusọ yín ṣọ̀tẹ̀ sí mi.
Ithe wanyu wa mbere nĩehirie; nao andũ arĩa maaragia ithenya rĩanyu makĩĩnemera.
28 Nítorí náà, èmi ti sọ àwọn olórí ibi mímọ́ náà di àìmọ́, bẹ́ẹ̀ ni èmi ti fi Jakọbu fún ègún àti Israẹli fún ẹ̀gàn.
Nĩ ũndũ ũcio-rĩ, nĩngaconorithia anene a hekarũ yanyu, na ndũme Jakubu anangĩke, o nake Isiraeli atuĩke wa kũnyararwo.

< Isaiah 43 >