< Isaiah 42 >

1 “Ìránṣẹ́ mi nìyìí, ẹni tí mo gbéró, àyànfẹ́ mi nínú ẹni tí mo láyọ̀; Èmi yóò fi Ẹ̀mí mi sínú rẹ̀ òun yóò sì mú ìdájọ́ wá sórí àwọn orílẹ̀-èdè.
“Atĩrĩrĩ, ĩno nĩyo ndungata yakwa, ĩrĩa ndiiragĩrĩra, ĩrĩa ndĩthuurĩire na nĩyo ĩkenagia ngoro yakwa; nĩngamĩitĩrĩria Roho wakwa nayo nĩĩkarehithĩria ndũrĩrĩ ciira wa kĩhooto.
2 Òun kì yóò pariwo tàbí kígbe sókè, tàbí kí ó gbóhùn rẹ̀ sókè ní òpópónà.
Ndĩkaanĩrĩra kana ĩgũũthũke, kana mũgambo wayo ũiguuo kũu njĩra-inĩ.
3 Koríko odò títẹ̀ kan ni òun kì yóò fọ́, àti òwú-fìtílà tí ń jó tan an lọ lòun kì yóò fẹ́ pa. Ní òdodo ni yóò mú ìdájọ́ wá;
Kamũrangi kagondoku ndĩgakoina, kana ĩhorie rũtambĩ rwa ũguta rũrĩa rũratooga. Na nĩ ũndũ wa wĩhokeku nĩĩgatuanĩra ciira na kĩhooto;
4 òun kì yóò kọsẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni kò ní rẹ̀wẹ̀sì títí tí yóò fi fi ìdájọ́ múlẹ̀ ní ayé. Nínú òfin rẹ̀ ni àwọn erékùṣù yóò fi ìrètí wọn sí.”
ndĩgaatithia kana ĩkue ngoro nginya hĩndĩ ĩrĩa ĩgaatũma gũkũ thĩ kũgĩe ciira wa kĩhooto. Andũ arĩa matũũraga icigĩrĩra-inĩ makehoka watho wayo.”
5 Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run wí Ẹni tí ó dá àwọn ọ̀run tí ó sì tẹ́ wọ́n sóde, tí ó tẹ́ ilẹ̀ ayé àti ohun gbogbo tí ó jáde nínú wọn, Ẹni tí ó fún àwọn ènìyàn rẹ̀ ní èémí àti ẹ̀mí fún gbogbo àwọn tí ń rìn nínú rẹ̀:
Jehova, Mũrungu witũ, ũrĩa wombire igũrũ na akĩrĩtambũrũkia, o we ũrĩa waraganirie thĩ na indo iria ciothe ciumaga kuo, na nĩwe ũheaga andũ a thĩ mĩhũmũ, na akahe arĩa maikaraga kuo muoyo, ekuuga atĩrĩ:
6 “Èmi, Olúwa, ti pè ọ́ ní òdodo, Èmi yóò di ọwọ́ rẹ mú. Èmi yóò pa ọ́ mọ́, n ó sì ṣe ọ́ láti jẹ́ májẹ̀mú fún àwọn ènìyàn àti ìmọ́lẹ̀ fún àwọn aláìkọlà
“Niĩ Jehova nĩ niĩ ngwĩtĩte na njĩra ya ũthingu; nĩngakũnyiita guoko. Nĩngakũmenyagĩrĩra na ngũheane ũtuĩke wa kũrĩkanĩra kĩrĩkanĩro na andũ, o na ũtuĩke ũtheri wa gũtherera andũ a Ndũrĩrĩ,
7 láti la àwọn ojú tí ó fọ́, láti tú àwọn òǹdè kúrò nínú túbú àti láti tú sílẹ̀ kúrò nínú ẹ̀wọ̀n àwọn tí ó jókòó nínú òkùnkùn.
na nĩguo ũhingũrage atumumu maitho, na wohorithagie arĩa mohetwo ũmarute moime njeera, o nao arĩa maikarĩte nduma-inĩ ũmarekererie, moime korokoro-inĩ.
8 “Èmi ni Olúwa; orúkọ mi nìyìí! Èmi kì yóò fi ògo mi fún ẹlòmíràn tàbí ìyìn mi fún ère òrìṣà.
“Nĩ niĩ Jehova; rĩu nĩrĩo rĩĩtwa rĩakwa! Naguo riiri wakwa ndikaũhe mũndũ ũngĩ, kana njĩtĩkĩre mĩhianano ya kũhooywo ĩheo ũgooci wakwa.
9 Kíyèsi i, àwọn nǹkan àtijọ́ ti wáyé, àti àwọn nǹkan tuntun ni mo ti wí pé; kí wọn tó hù jáde mo ti kéde rẹ̀ fún ọ.”
Atĩrĩrĩ, maũndũ maarathirwo tene nĩmahingĩtio, na rĩu nĩ maũndũ merũ ngwanĩrĩra; na maũndũ macio matanakinya-rĩ, nĩndĩmũmenyithĩtie ũhoro wamo.”
10 Kọ orin tuntun sí Olúwa ìyìn rẹ̀ láti òpin ilẹ̀ ayé wá, ẹ̀yin tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ sínú Òkun, àti ohun gbogbo tí ń bẹ nínú rẹ̀, ẹ̀yin erékùṣù, àti gbogbo àwọn tí ń gbé inú wọn.
Inĩrai Jehova rwĩmbo rwerũ, na mũmũgooce kuuma ituri-inĩ ciothe cia thĩ, inyuĩ mũikũrũkaga kũu iria-inĩ, na kĩrĩa gĩothe kĩrĩ thĩinĩ warĩo, o na inyuĩ icigĩrĩra, na arĩa othe matũũraga thĩinĩ wacio.
11 Jẹ́ kí aginjù àti àwọn ìlú rẹ̀ kí ó gbé ohùn wọn sókè; jẹ́ kí ibùdó ti àwọn ìlú Kedari ń gbé máa yọ̀. Jẹ́ kí àwọn ènìyàn Sela kọrin fún ayọ̀; jẹ́ kí wọn pariwo láti orí òkè.
Werũ na matũũra makuo nĩmanĩrĩre na mĩgambo; o na tũtũũra tũrĩa Kedari atũũraga nĩtũkũngũĩre. Andũ a Sela nĩmarekwo maine rwĩmbo nĩ gũkena; o na mũreke maanĩrĩre marĩ kũu irĩma-igũrũ.
12 Jẹ́ kí wọn fi ògo fún Olúwa àti kí wọn sì kéde ìyìn rẹ̀ ní erékùṣù.
Nĩmarekwo makumie Jehova, na maanĩrĩre ũgooci wake kũu icigĩrĩra-inĩ.
13 Olúwa yóò rìn jáde gẹ́gẹ́ bí i ọkùnrin alágbára, yóò ru owú sókè bí ológun; yóò kígbe nítòótọ́, òun yóò ké igbe ogun, òun yóò sì ṣẹ́gun àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Jehova nĩakoimagara athiĩ o ta njamba ĩrĩ hinya, na aarahũre kĩyo gĩake ta njamba ya ita; akaanĩrĩra na oigĩrĩrie mbugĩrĩrio ya mbaara, na nĩagatooria thũ ciake.
14 “Fún ìgbà pípẹ́ ni mo ti dákẹ́ jẹ́ẹ́, mo ti wà ní ìdákẹ́ jẹ́ẹ́, mo sì kó ara ró. Ṣùgbọ́n ní àkókò yìí, gẹ́gẹ́ bí obìnrin tí ó ń rọbí, mo sọkún, mo sì ń mí hẹlẹ hẹlẹ.
“Ihinda iraaya ngoretwo ngirĩte ki, ngegirĩrĩria gwĩka ũndũ. No rĩu-rĩ, ndĩrakaya ta mũtumia ũrarũmwo, ngateeha na ngahũma.
15 Èmi yóò sọ òkè ńlá àti kékeré di ahoro tí n ó sì gbẹ gbogbo ewéko rẹ̀ dànù, Èmi yóò sọ àwọn odò di erékùṣù n ó sì gbẹ àwọn adágún.
Nĩngananga irĩma na tũrĩma, na ndũme mĩmera ĩrĩa yothe ĩkũraga kuo yũme; nĩngatũma njũũĩ ituĩke icigĩrĩra na ndũme tũria tũhwe.
16 Èmi yóò tọ àwọn afọ́jú ní ọ̀nà tí wọn kò tí ì mọ̀, ní ipa ọ̀nà tí ó ṣàjèjì sí wọn ni èmi yóò tọ́ wọn lọ; Èmi yóò sọ òkùnkùn di ìmọ́lẹ̀ níwájú wọn àti ibi pálapàla ni èmi ó sọ di kíkúnná. Àwọn nǹkan tí máa ṣe nìyìí; Èmi kì yóò kọ̀ wọ́n sílẹ̀.
Nao atumumu nĩngamagereria njĩra iria matooĩ, na ndĩmatoongorerie tũcĩra tũrĩa mataahũthĩrĩte gũthiĩra; nayo nduma nĩngamĩgarũra ĩtuĩke ũtheri mbere yao, nakuo kũndũ kũrĩa gũtarĩ kũigananu ndĩkwaraganie. Maũndũ macio nĩmo ngeeka, na ndikamatiganĩria.
17 Ṣùgbọ́n àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé òrìṣà, tí wọ́n wí fún ère pé, ‘Ẹ̀yin ni Ọlọ́run wa,’ ni a ó dá padà pẹ̀lú ìtìjú.
No rĩrĩ, andũ arĩa mehokete mĩhianano ya kũhooywo, o acio meraga mĩhianano ya gwacũhio atĩrĩ, ‘Inyuĩ nĩ inyuĩ ngai ciitũ,’ nĩmakahũndũrwo na nĩmagaconorithio kũna.
18 “Gbọ́, ìwọ adití, wò ó, ìwọ afọ́jú, o sì rí!
“Inyuĩ mũtaiguaga, ta iguai, na inyuĩ atumumu-rĩ, ta cũthĩrĩriai, nĩguo muone!
19 Ta ló fọ́jú bí kò ṣe ìránṣẹ́ mi, àti odi gẹ́gẹ́ bí oníṣẹ́ tí mo rán? Ta ni ó fọ́jú gẹ́gẹ́ bí ẹni tí a fi jìnmí, ó fọ́jú gẹ́gẹ́ bí ìránṣẹ́ Olúwa?
Nũũ mũtumumu tiga o ndungata yakwa, o na kana nũũ ũtaiguaga ta mũtũmwo ũcio ndũmĩte? Nũũ mũtumumu ta ũrĩa wĩheanĩte biũ kũrĩ niĩ, na nũũ mũtumumu ta ndungata ya Jehova?
20 Ẹ̀yin ti rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan, ṣùgbọ́n ẹ kò ṣe àkíyèsí; etí yín yà sílẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ kò gbọ́ nǹkan kan.”
Nĩwonete maũndũ maingĩ, no ndũmarũmbũyagia; matũ maku nĩmahingũrĩtwo, no ndũrĩ ũndũ ũiguaga.”
21 Ó dùn mọ́ Olúwa nítorí òdodo rẹ̀ láti mú òfin rẹ lágbára àti ògo.
Jehova nĩonire arĩ wega atũũgĩrie watho wake na ũgĩe riiri nĩ ũndũ wa ũthingu wake.
22 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn kan nìyìí tí a jà lógun tí a sì kó lẹ́rú, gbogbo wọn ni ó wà nínú ọ̀gbun, tàbí tí a fi pamọ́ sínú ẹ̀wọ̀n. Wọ́n ti di ìkógun, láìsí ẹnìkan tí yóò gbà wọ́n sílẹ̀; wọ́n ti di ìkógun, láìsí ẹni tí yóò sọ pé, “Dá wọn padà.”
No rĩrĩ, andũ aya nĩmatahĩtwo na magatunywo indo, othe manyiitĩtwo na mĩtego marima-inĩ, o na makahithwo njeera thĩinĩ. Matuĩkĩte ta nyamũ cia kũguĩmwo, na gũtirĩ mũndũ ũngĩmahonokia; maikarĩte marĩ atahe, na gũtirĩ mũndũ ũngiuga atĩrĩ, “Nĩmacookio kwao.”
23 Ta ni nínú yín tí yóò tẹ́tí sí èyí tàbí kí ó ṣe àkíyèsí gidi ní àsìkò tí ó ń bọ̀?
Nũũ wanyu ũgũthikĩrĩria ũhoro ũyũ, kana aũrũmbũiye mahinda marĩa magooka?
24 Ta ni ó fi Jakọbu lélẹ̀ fún ìkógun, àti Israẹli sílẹ̀ fún onísùnmọ̀mí? Kì í ha ṣe Olúwa ni, ẹni tí àwa ti ṣẹ̀ sí? Nítorí pé wọn kò ní tẹ̀lé ọ̀nà rẹ̀; wọn kò mú òfin rẹ̀ ṣẹ.
Nũũ waneanire Jakubu atuĩke wa gũtahwo, na nũũ waneanire Isiraeli kũrĩ atunyani? Githĩ ti Jehova, o ũrĩa ithuĩ twĩhĩirie? Nĩgũkorwo andũ nĩmaregire gũthiĩ na njĩra ciake; nĩmagire gwathĩkĩra watho wake.
25 Nítorí náà ni ó ṣe rọ̀jò ìbínú un rẹ̀ lé wọn lórí, rògbòdìyàn ogun. Èyí tí ó fi ahọ́n iná yí wọn po, síbẹ̀ èdè kò yé wọn; ó jó wọn run, síbẹ̀ wọn kò fi sọ́kàn wọn rárá.
Nĩ ũndũ ũcio nĩamaitĩrĩirie marakara make mahiũ, na akĩmatharĩkĩra na mbaara. Maarigiicĩirio nĩ marakara mahaana ta nĩnĩmbĩ cia mwaki mĩena yothe, no-o matiigana kũmenya. Marakara macio makĩmacina, no matiigana kũrũmbũiya ũhoro ũcio ngoro-inĩ ciao.

< Isaiah 42 >