< Genesis 23 >
1 Sara sì pé ọmọ ọdún mẹ́tàdínláàádóje.
Saraⱨ bir yüz yigirmǝ yǝttǝ yaxⱪiqǝ ɵmür kɵrdi. Bu Saraⱨning ɵmrining yilliri idi.
2 Ó sì kú ní Kiriati-Arba (ìyẹn ní Hebroni) ní ilẹ̀ Kenaani, Abrahamu lọ láti ṣọ̀fọ̀ àti láti sọkún nítorí Sara.
Saraⱨ Ⱪanaan zeminidiki Kiriat-Arba, yǝni Ⱨebronda wapat boldi. Ibraⱨim berip Saraⱨ üqün matǝm tutup yiƣa-zar ⱪildi.
3 Abrahamu sì dìde lẹ́gbẹ̀ẹ́ òkú aya rẹ̀, ó sì sọ fún àwọn ará Hiti wí pé,
Ibraⱨim ɵz mǝrⱨumǝsining yenidin ⱪopup, Ⱨittiylarƣa sɵz ⱪilip:
4 “Èmi jẹ́ àtìpó àti àlejò láàrín yín, ẹ ta ilẹ̀ ìsìnkú fún mi kí èmi le sin òkú tí ó kú fún mi sí.”
— Mǝn bolsam aranglarda musapir meⱨman, halas; silǝr ǝmdi aranglardin manga bir yǝrlik beringlar; xuning bilǝn mǝn bu mǝrⱨumǝmni aldimda kɵrünüp turmisun üqün elip berip dǝpnǝ ⱪilay, — dedi.
5 Àwọn ọmọ Hiti dá Abrahamu lóhùn pé,
Ⱨittiylar Ibraⱨimƣa jawab berip: — I hojam, bizgǝ ⱪulaⱪ salƣayla! Sili arimizda Hudaning bir xaⱨzadisi ⱨesablinila! Arimizdiki ǝng esil yǝrlikni tallap, xu yǝrdǝ mǝrⱨumǝlirini dǝpnǝ ⱪilƣayla! Mǝrⱨumǝlirini dǝpnǝ ⱪilixⱪa ⱨeqⱪaysimiz ɵz yǝrlikini silidin ayimaydu, — dedi.
6 “Olúwa mi, gbọ́ tiwa, ó jẹ́ alágbára ọmọ-aládé láàrín wa, sin òkú rẹ sí ibojì tí ó dára jù nínú àwọn ibojì wa, kò sí ẹni tí yóò fi ibojì rẹ dù ọ́ láti sin òkú rẹ sí.”
7 Nígbà náà ni Abrahamu dìde, ó sì tẹríba níwájú àwọn ará ilẹ̀ náà, àwọn ará Hiti.
Ibraⱨim ornidin turup, u zemindiki hǝlⱪⱪǝ, yǝni Ⱨittiylarƣa tǝzim ⱪilip,
8 Ó sì wí fún wọn pé, “Bí ó bá ṣe pé, lóòótọ́ ni ẹ fẹ́ kí n sin òkú mi kúrò nílẹ̀, ẹ gbọ́ tèmi, ẹ bá mi bẹ Efroni ọmọ Sohari,
ularƣa: — Əgǝr mǝrⱨumǝmning kɵz aldimda turiwǝrmǝsliki üqün, uni elip berip, dǝpnǝ ⱪiliximni rawa kɵrsǝnglar, undaⱪta sɵzümni anglap mening üqün Zoⱨarning oƣli Əfronƣa sɵz ⱪilip,
9 kí ó ta ihò àpáta Makpela tí ó jẹ́ tirẹ̀ fún mi, èyí tí ó wà ni orí oko rẹ̀, kí ó tà á fún mi ni iye owó tí à ń ta irú rẹ̀ fún ilẹ̀ ìsìnkú láàrín yín.”
uning etizining ayiƣida ɵziningki bolƣan Makpelaⱨning ƣarini manga berixini iltimas ⱪilinglar. U manga buni silǝrning aranglarda gɵristan boluxⱪa toluⱪ nǝrhidǝ bǝrsun, — dedi.
10 Efroni ará Hiti sì wà níbẹ̀ pẹ̀lú, ó sì dá Abrahamu lóhùn lójú gbogbo àwọn ará ìlú tí ó wà níbẹ̀, lẹ́nu ibodè ìlú,
Xu qaƣda Əfron Ⱨittiylar arisida olturatti. Xuning bilǝn ⱨittiyliⱪ Əfron Ⱨittiylarning aldida, yǝni xǝⱨirining dǝrwazisidin kirgüqilǝrning ⱨǝmmisining aldida Ibraⱨimƣa jawab berip: —
11 pé, “Rárá, olúwa mi. Gbọ́ tèmi; mo fún ọ ní ilẹ̀ náà àti ihò àpáta tí ó wà níbẹ̀. Mo fún ọ níwájú gbogbo àwọn ènìyàn mi. Sin òkú rẹ síbẹ̀.”
Yoⱪsu, ǝy hojam, manga ⱪulaⱪ salƣayla. Bu etizliⱪni, xundaⱪla uningdiki ƣarni siligǝ berǝy; uni ɵz hǝlⱪim bolƣan adǝmlǝrning aldida siligǝ bǝrdim; ɵz meyitlirini dǝpnǝ ⱪilƣayla, — dedi.
12 Abrahamu sì tún tẹríba níwájú àwọn ènìyàn ìlú náà,
Andin Ibraⱨim yǝnǝ zemin hǝlⱪi aldida tǝzim ⱪilip,
13 ó sì wí fún Efroni lójú gbogbo wọn pé, “Bí ìwọ bá fẹ́, gbọ́ tèmi, èmi yóò san owó ilẹ̀ náà, gbà á lọ́wọ́ mi kí n lè sin òkú mi síbẹ̀.”
Xu zemindiki hǝlⱪning ⱪulaⱪliri aldida Əfronƣa: — Iltimasimƣa ⱪulaⱪ salƣayla; mǝn bu etizliⱪning nǝrhi boyiqǝ pul berǝy, uni mǝndin ⱪobul ⱪilƣayla, andin mǝn meyitimni xu yǝrdǝ dǝpnǝ ⱪilay, — dedi.
14 Efroni sì dá Abrahamu lóhùn pé,
Əfron Ibraⱨimƣa jawab berip uningƣa:
15 “Gbọ́ tèmi Olúwa mi, irinwó òsùwọ̀n owó fàdákà ni ilẹ̀ náà, ṣùgbọ́n kín ni ìyẹn já mọ láàrín àwa méjèèjì? Sá à sin òkú rẹ.”
Əy hojam, manga ⱪulaⱪ salƣayla; tɵt yüz xǝkǝl kümüxkǝ yaraydiƣan bir etizliⱪ, sili bilǝn mening aramda nemǝ idi? Sili meyitlirini dǝpnǝ ⱪilƣayla — dedi.
16 Abrahamu sì gbọ́ tí Efroni wí, Abrahamu sì wọn iye fàdákà náà fún Efroni, tí ó sọ ní etí àwọn ọmọ Hiti, irinwó òsùwọ̀n ṣékélì fàdákà, tí ó kọjá lọ́dọ̀ àwọn oníṣòwò.
Ibraⱨim Əfronning sɵzigǝ ⱪoxuldi; andin Əfron Ⱨittiylar aldida eytⱪan baⱨani, yǝni xu qaƣdiki soda ɵlqimi boyiqǝ tɵt yüz xǝkǝl kümüxni tarazida tartip bǝrdi.
17 Báyìí ni ilẹ̀ Efroni tí ó wà ni Makpela nítòsí Mamre, ilẹ̀ náà àti ihò àpáta tí ó wà nínú rẹ̀ àti gbogbo igi tí ó wà nínú ilẹ̀ náà ni a ṣe ètò rẹ̀ dájú,
Xundaⱪ ⱪilip Mamrǝning udulidiki Makpelaⱨⱪa jaylaxⱪan Əfronning etizliⱪi, yǝni etizliⱪning ɵzi, uningdiki ƣar, xundaⱪla etizliⱪning iqi wǝ ǝtrapidiki barliⱪ dǝrǝhlǝrning ⱨǝmmisi
18 bí ohun ìní fún Abrahamu níwájú gbogbo ará Hiti tí ó wá sí ẹnu ibodè ìlú náà.
Ⱨittiylarning kɵz aldida Ibraⱨimƣa tapxurulup, [yǝni Əfronning] xǝⱨirining dǝrwazisidin barliⱪ kirgüqilǝrning aldida uning mülki ⱪilip bekitildi.
19 Lẹ́yìn náà ni Abrahamu sin aya rẹ̀ Sara sínú ihò àpáta ní ilẹ̀ Makpela nítòsí Mamre (tí í ṣe Hebroni) ní ilẹ̀ Kenaani.
Xuningdin keyin Ibraⱨim ayali Saraⱨni Ⱪanaan zeminidiki Mamrǝ (yǝni, Ⱨebron)ning udulidiki Makpelaⱨning etizliⱪining ƣarida dǝpnǝ ⱪildi.
20 Ilẹ̀ náà àti ihò àpáta tí ó wà nínú rẹ̀ ni àwọn ará Hiti fi fún Abrahamu gẹ́gẹ́ bí ohun ìní títí láé, bí ilẹ̀ ìsìnkú fún àwọn òkú tí ó bá kú fun un.
Xu tǝriⱪidǝ u etizliⱪ wǝ uningdiki ƣar Ⱨittiylar tǝripidin Ibraⱨimƣa gɵristan boluxⱪa tayin ⱪilindi.