< Genesis 16 >

1 Sarai, aya Abramu kò bímọ fún un, ṣùgbọ́n ó ní ọmọ ọ̀dọ̀ obìnrin ará Ejibiti kan tí ń jẹ́ Hagari.
Leleꞌ naa, Abram baliꞌ mia Masir, de leo sia Kanaꞌan too sanahulu ena. Sao na Sarai, nda feꞌe ma anaꞌ sa. Te Sarai ma ate inaꞌ mia Masir, naran Hagar. Lao esa ma, Sarai ola-olaꞌ no Abram nae, “Aꞌa! LAMATUALAIN babata mamana ana ngga ena. De malole lenaꞌ, muu sungguꞌ mo ate ngga Hagar, fo ana bꞌonggi fee au.” Abram tungga sao na oꞌola na boe. De Sarai fee Hagar dadꞌi Abram sao muri na.
2 Nítorí náà, Sarai wí fún Abramu pé, “Kíyèsi i Olúwa ti sé mi ní inú, èmi kò sì bímọ, wọlé tọ ọmọ ọ̀dọ̀ mi lọ, bóyá èmi yóò le ti ipasẹ̀ rẹ̀ ní ọmọ.” Abramu sì gba ohun tí Sarai sọ.
3 Lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá tí Abramu ti ń gbé ni Kenaani ni Sarai mú ọmọbìnrin, ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ Hagari, tí í ṣe ará Ejibiti fún Abramu ọkọ rẹ̀ láti fi ṣe aya.
4 Abramu sì bá Hagari lòpọ̀, ó sì lóyún. Nígbà tí ó sì ti mọ̀ pé òun lóyún, ó bẹ̀rẹ̀ sì ní kẹ́gàn ọ̀gá rẹ̀.
Boe ma Abram neu sungguꞌ no Hagar, de nairu. Hagar bubꞌuluꞌ eni mairuꞌ ma, ana koao, de naloe Sarai.
5 Nígbà náà ni Sarai wí fún Abramu pé, “Ìwọ ni ó jẹ́ kí ẹ̀gbin yìí máa jẹ mí, mo fa ọmọ ọ̀dọ̀ mi lé ọ lọ́wọ́, nígbà tí ó sì rí i pé òun lóyún, mo di ẹni ẹ̀gàn ní ojú rẹ̀. Kí Olúwa kí ó ṣe ìdájọ́ láàrín tèmi tìrẹ.”
Boe ma Sarai olaꞌ no Abram nae, “Au mana fee ate naa fo dadꞌi sao muri ma. Te ana bubꞌuluꞌ eni mairuꞌ, ma naloe-nadꞌae au. Ia, ho sala ma! Hela fo LAMATUALAIN naꞌetuꞌ hita ruꞌa nggita dedꞌea na. Dei fo ho bubꞌuluꞌ!”
6 Abramu dáhùn pé, “Ìwọ ló ni ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ, ṣe ohunkóhun tí ó bá tọ́ ní ojú rẹ sí i.” Nígbà náà ni Sarai fi ìyà jẹ Hagari, ó sì sálọ.
Abram nataa nae, “Taꞌo ia! Ho ia, sao ulu ngga. Eni, sao muriꞌ a. Dadꞌi muꞌena koasa neu e. Mae tao saa mbali e, siaꞌ a nggo!” Boe ma Sarai tao suka-ranggaꞌ e, losa ana nela.
7 Angẹli Olúwa sì rí Hagari ní ẹ̀gbẹ́ ìsun omi ní ijù, ìsun omi tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ ọ̀nà tí ó lọ sí Ṣuri.
Hagar nela losa nembe saraꞌae ma, LAMATUALAIN ate na esa mia sorga, hambu e deka no oe mataꞌ sia dalaꞌ mana nisiꞌ Sur.
8 Ó sì wí pé, “Hagari, ìránṣẹ́ Sarai, níbo ni o ti ń bọ̀, níbo sì ni ìwọ ń lọ?” Ó sì dáhùn pé, “Mo ń sálọ kúrò lọ́dọ̀ ọ̀gá mi Sarai ni.”
Ana nae, “We! Hagar, Sarai ate na! Taꞌo bee de ho sia ia? Mia bee uma ma mae bee muu?” Nataa nae, “Au lao hela nyora ngga.”
9 Angẹli Olúwa sì wí fún un pé, “Padà lọ sí ọ̀dọ̀ ọ̀gá rẹ kí o sì tẹríba fún un.”
De LAMATUALAIN ate na kokoe nae, “Taꞌo ia! Malole lenaꞌ baliꞌ misiꞌ nyora ma. Ana tao nggo taꞌo bee o, simboꞌ a.
10 Angẹli Olúwa náà sì fi kún fún un pé, “Èmi yóò sọ ọ́ di orílẹ̀-èdè ńlá, ìran rẹ kì yóò sì lóǹkà.”
Afiꞌ mumutau. Dei fo au tao tititi-nonosi ma ramaheta, losa atahori nda reken rala se sa.
11 Angẹli Olúwa náà sì wí fún un pé, “Ìwọ ti lóyún, ìwọ yóò sì bí ọmọkùnrin kan. Ìwọ yóò sì pe orúkọ rẹ̀ ní Iṣmaeli, nítorí tí Olúwa ti rí ìpọ́njú rẹ.
Ho mairuꞌ ena, de nda dooꞌ sa te, bꞌonggi ana touꞌ esa. Musi babꞌae e Ismael (lii na naeꞌ a onaꞌ dedꞌea feaꞌ esa sosoa na ‘Lamatuaꞌ rena’), huu LAMATUALAIN rena haradꞌoi ma.
12 Òun yóò jẹ́ oníjàgídíjàgan ènìyàn ọwọ́ rẹ̀ yóò wà lára ènìyàn gbogbo, ọwọ́ ènìyàn gbogbo yóò sì wà lára rẹ̀, yóò sì máa gbé ní ìkanra pẹ̀lú àwọn arákùnrin rẹ̀.”
Anaꞌ naa naꞌamoko nema, nasodꞌa naꞌadꞌoodꞌoꞌ no bobꞌonggi nara. Huu ana onaꞌ ndara fui e, nda rena parendaꞌ sa. Ana labꞌan sudꞌi a se. Ma basa atahori labꞌan baliꞌ e.”
13 Ó sì pe orúkọ Olúwa tí o bá sọ̀rọ̀ ní, “Ìwọ ni Ọlọ́run tí ó rí mi,” nítorí tí ó wí pé, “Mo ti ri ẹni tí ó rí mi báyìí.”
Hagar rena nala ma, ana olaꞌ sia rala na nae, “Au ita LAMATUALAIN, mana mete-seꞌu ma nanea au.” De ana noꞌe Lamatualain, no naraꞌ “Lamatualain mana fadꞌuli au.”
14 Nítorí náà ni a ṣe ń pe kànga náà ní Beeri-Lahai-Roi; kànga ẹni alààyè tí ó rí mi. Ó wà ní agbede-méjì Kadeṣi àti Beredi.
Naa de, atahori babꞌae oe mataꞌ naa, naran, Beer Lahai Roi. Sosoa na oi, “Oe mataꞌ mia Mana masodꞌaꞌ, ma Mana mete-seꞌu au.” Oe mataꞌ naa, sia kambo Kades no kambo Beret taladꞌa na. Oe mataꞌ naa feꞌe sia, losa faiꞌ ia.
15 Hagari sì bí ọmọkùnrin kan fún Abramu, Abramu sì pe orúkọ rẹ̀ ní Iṣmaeli.
Basa naa ma, Hagar baliꞌ, de bꞌonggi ana touꞌ esa. Abram babꞌae e Ismael.
16 Abramu jẹ́ ẹni ọdún mẹ́rìndínláàádọ́rùn-ún nígbà tí Hagari bí Iṣmaeli fún un.
Hagar bꞌonggi Ismael te, Abram too falu nulu nee ena.

< Genesis 16 >