< Genesis 13 >
1 Abramu sì gòkè láti Ejibiti lọ sí ìhà gúúsù, pẹ̀lú aya rẹ̀ àti ohun gbogbo tí ó ní àti Lọti pẹ̀lú.
Basa ma, Abram lao hela Masir, de baliꞌ nisiꞌ rae Negeb. Neu no sao na, ma basa hata-heto na. Odꞌi na anan Lot o tungga e boe.
2 Abramu sì ti di ọlọ́rọ̀ gidigidi; ní ẹran ọ̀sìn, ó ní fàdákà àti wúrà.
Abram ia, mamasuꞌin seli. Banda neꞌeboiꞌ, lilo mbilas ma doi fulaꞌ, nae na seli.
3 Láti gúúsù, ó ń lọ láti ibìkan sí ibòmíràn títí ó fi dé ilẹ̀ Beteli, ní ibi tí àgọ́ rẹ̀ ti wà ní ìṣáájú rí, lágbedeméjì Beteli àti Ai.
Mia Negeb ana lao lali-laliꞌ de baliꞌ nisiꞌ kambo Betel no Ai taladꞌa na. Dalahulu na, ana leo mia naa.
4 Ní ibi pẹpẹ tí ó ti tẹ́ síbẹ̀ ní ìṣáájú, níbẹ̀ ni Abramu sì ń ké pe orúkọ Olúwa.
Ana o lutu mbatu fatu dadꞌi mei tutunu-hohotuꞌ boe. De beꞌutee neu LAMATUALAIN sia naa.
5 Àti Lọti pẹ̀lú, tí ó ń bá Abramu rìn kiri, ní agbo ẹran, ọ̀wọ́ ẹran àti àgọ́.
Lot, mana tungga no Abram, naꞌena banda neꞌeboiꞌ naeꞌ, ma atahori mana tao ues o naeꞌ boe.
6 Ṣùgbọ́n ilẹ̀ náà kò le gbà wọ́n tí wọ́n bá ń gbé pọ̀, nítorí, ohun ìní wọn pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́, dé bi wí pé wọn kò le è gbé pọ̀.
Te mamanaꞌ naa nda loaꞌ, soaꞌ neu Abram no Lot, no basa hata-heto nara fo rasodꞌa sa. De manatadꞌa nara rareresi, huu uru nda dai banda nara sa. (Leleꞌ naa, atahori Kanaꞌan ro atahori Feris o feꞌe leo sia naa boe.)
7 Èdè-àìyedè sì bẹ̀rẹ̀ láàrín àwọn darandaran Abramu àti ti Lọti. Àwọn ará Kenaani àti àwọn ará Peresi sì ń gbé ní ilẹ̀ náà nígbà náà.
8 Abramu sì wí fún Lọti pé, “Èmi bẹ̀ ọ́, má ṣe jẹ́ kí èdè-àìyedè kí ó wà láàrín èmi àti ìrẹ, àti láàrín àwọn darandaran wa, nítorí pé ẹbí kan ni àwa ṣe.
De Abram nafadꞌe ana na nae, “Lot, e! Hita ia bobꞌonggiꞌ. Afiꞌ losa hita esa nda maloleꞌ no esa sa, huu atahori mana tao ues tara ratofa rakandooꞌ a.
9 Gbogbo ilẹ̀ ha kọ́ nìyí níwájú rẹ? Jẹ́ kí a pínyà. Bí ìwọ bá lọ sí apá ọ̀tún, èmi yóò lọ sí apá òsì, bí ó sì ṣe òsì ni ìwọ lọ, èmi yóò lọ sí apá ọ̀tún.”
Dadꞌi malole lenaꞌ ruꞌa nggita saranggaa. Mamanaꞌ ia loaꞌ, de mete ma hii mala rae seriꞌ dii, naa au isiꞌ seriꞌ ona. Mete ma hii mala seriꞌ ona, naa au isiꞌ seriꞌ dii.”
10 Lọti sì gbójú sókè, ó sì ri wí pé gbogbo pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jordani ni omi rin dáradára bí ọgbà Olúwa, bí ilẹ̀ Ejibiti, ní ọ̀nà Soari. (Èyí ní ìṣáájú kí Olúwa tó pa Sodomu àti Gomorra run.)
Boe ma Lot mete rereoꞌ, de nita babafaꞌ loe Yordan oe na naeꞌ losa kambo Soar. Mamanaꞌ naa maꞌasufuꞌ onaꞌ LAMATUALAIN osi na, ma onaꞌ rae Masir. (Leleꞌ naa, LAMATUALAIN nda feꞌe tao nalutu kambo Sodꞌom no Gomora sa. De rae naa feꞌe maloleꞌ.)
11 Nítorí náà Lọti yan gbogbo pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jordani yìí fún ara rẹ̀, ó sì ń lọ sí ọ̀nà ìlà-oòrùn. Òun àti Abramu sì pínyà.
Dadꞌi Lot hii nala basa rae sia babafaꞌ loe Yorden. De ruꞌa se saranggaa ma, Lot nisiꞌ seriꞌ rulu.
12 Abramu ń gbé ni ilẹ̀ Kenaani, Lọti sì jókòó ní ìlú agbègbè àfonífojì náà, ó sì pàgọ́ rẹ̀ títí dé Sodomu.
Te Abram leo nahati rae Kanaꞌan. Lot neu leo sia kambo-kamboꞌ deka Sodꞌom sia babafaꞌ Yarden.
13 Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin Sodomu jẹ́ ènìyàn búburú, wọn sì ń dẹ́ṣẹ̀ gidigidi ni iwájú Olúwa.
Atahori Sodꞌom ra, deꞌulaka nara seli ma nda nau rena LAMATUALAIN sa.
14 Olúwa sì wí fún Abramu lẹ́yìn ìpinyà òun àti Lọti pé, “Gbé ojú rẹ sókè nísinsin yìí, kí o sì wò láti ibi tí o gbé wà a nì lọ sí ìhà àríwá àti sí ìhà gúúsù, sí ìlà-oòrùn àti sí ìwọ̀ rẹ̀.
Lot no Abram saranggaa ma, LAMATUALAIN olaꞌ no Abram nae, “Abram! Sobꞌa mete rereoꞌ basa mamanaꞌ mia mamanaꞌ ho mumburiꞌ siaꞌ a. Mete malolole deaꞌ-mataꞌ ma dii-ona.
15 Gbogbo ilẹ̀ tí ìwọ ń wò o nì ni èmi ó fi fún ọ àti irú-ọmọ rẹ láéláé.
Basa rae fo mitaꞌ naa, dei fo Au fee neu nggo, mo tititi-nonosi mara, fo dadꞌi hata-heto ma losa doo na neu.
16 Èmi yóò mú kí irú-ọmọ rẹ kí ó pọ̀ bí erùpẹ̀ ilẹ̀, tó bẹ́ẹ̀ tí ó bá ṣe pé ẹnikẹ́ni bá le è ka erùpẹ̀ ilẹ̀, nígbà náà ni yóò tó lè ka irú-ọmọ rẹ.
Dei fo Au fee tititi-nonosi mara ramaheta onaꞌ saraꞌaeꞌ sia tasi suu na, losa atahori nda reken rala se sa.
17 Dìde, rìn òró àti ìbú ilẹ̀ náà já, nítorí ìwọ ni Èmi yóò fi fún.”
De ia naa, muu laoꞌ rereoꞌ rae a loa-naru na. Te dei fo, Au fee basa naa ra neu nggo!”
18 Nígbà náà ni Abramu kó àgọ́ rẹ̀, ó sì wá, ó sì jókòó ní ẹ̀gbẹ́ igi ńlá igbó Mamre, tí ó wà ní Hebroni. Níbẹ̀ ni ó gbé tẹ́ pẹpẹ kan sí fún Olúwa.
Basa ma, Abram se lali, reu leo baliꞌ sia mamanaꞌ deka hau-hau huu ineꞌ sia Mamre, deka kambo Hebron. Ana lutu mbatu mei tutunu-hohotuꞌ, de beꞌutee neu LAMATUALAIN sia naa.