< Ezekiel 15 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá wí pé:
Wǝ Pǝrwǝrdigarning sɵzi manga kelip mundaⱪ deyildi: —
2 “Ọmọ ènìyàn, báwo ni igi àjàrà ṣe dára ju igi mìíràn lọ tàbí jù ẹ̀ka àjàrà tó wà láàrín igi yòókù nínú igbó?
«I insan oƣli, üzüm teli yaƣiqining baxⱪa dǝrǝh yaƣaqliridin nemǝ artuⱪqiliⱪi bar, uning xehining ormandiki dǝrǝhlǝr arisida nemǝ alaⱨidiliki bar?
3 Ǹjẹ́ a wa lè mú igi lára rẹ̀ ṣe nǹkan tí ó wúlò bí? Tàbí kí ènìyàn fi ṣe èèkàn tí yóò fi nǹkan kọ́?
Uningdin birǝr jabduⱪni yasaxⱪa materiyal alƣanning paydisi barmu? Uningdin qinilǝrni asⱪudǝk ⱪozuⱪni yasiƣili bolamdu?
4 Lẹ́yìn èyí, ṣe a jù ú sínú iná gẹ́gẹ́ bí epo ìdáná, gbogbo igun rẹ̀ jóná pẹ̀lú àárín rẹ, ṣé o wà le wúlò fún nǹkan kan mọ́?
Mana, u otⱪa yeⱪilƣu bolƣanda, ot uning ikki uqini kɵydürgǝndǝ, otturisimu yerim kɵygǝndǝ, ǝmdi uni birǝr ixⱪa ixlǝtkili bolamdu?
5 Tí kò bá wúlò fún nǹkan kan nígbà tó wà lódidi, báwo ni yóò ṣe wá wúlò nígbà tí iná ti jó o, tó sì dúdú nítorí èéfín?
Mana, u saⱪ bolƣanda, ⱨeqⱪandaⱪ ixⱪa ixlǝtkili bolmiƣan yǝrdǝ, ǝmdi ot uni kɵydürüp yǝp kǝtkǝndǝ, uni birǝr ixⱪa ixlǝtkili bolamdu?
6 “Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, bí mo ṣe sọ igi àjàrà tó wà láàrín àwọn igi inú igbó yòókù di igi ìdáná, bẹ́ẹ̀ ni Èmi yóò ṣe ṣe gbogbo ènìyàn tó ń gbé Jerusalẹmu.
Xunga Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: «Mǝn ormandiki dǝrǝhlǝr arisidiki üzüm telining yaƣiqini otⱪa tapxurƣinimdǝk, Yerusalemda turuwatⱪanlarni otⱪa tapxurimǝn.
7 Èmi yóò dojúkọ wọ́n. Bó tilẹ̀ jẹ́ pé wọn ti jáde kúrò nínú iná kan, síbẹ̀ iná mìíràn yóò pàpà jó wọn. Nígbà tí mo bá sì dojúkọ wọ́n, ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.
Yüzümni ularƣa ⱪarxi ⱪilip ⱪaritimǝn; ular bir ottin qiⱪsa, baxⱪa bir ot ularni yǝwetidu. Ɵz yüzümni ularƣa ⱪarxi bolup ⱪaratⱪanda, silǝr Mening Pǝrwǝrdigar ikǝnlikimni tonup yetisilǝr.
8 Èmi yóò sọ ilé náà di ahoro nítorí ìwà àìṣòótọ́ wọn, ni Olúwa Olódùmarè wí.”
Ularning ⱪilƣan wapasizliⱪliri tüpǝylidin mǝn zeminni wǝyranǝ ⱪilimǝn» — dǝydu Rǝb Pǝrwǝrdigar».

< Ezekiel 15 >