< Ezekiel 4 >

1 “Nísinsin yìí, ìwọ ọmọ ènìyàn, mú amọ̀ ṣíṣù kan, gbé e sí iwájú rẹ, kí o sì ya àwòrán ìlú Jerusalẹmu sí orí rẹ̀.
Əmdi sǝn, i insan oƣli, bir kesǝkni elip ɵz aldingƣa ⱪoyƣin; uning üstigǝ bir xǝⱨǝrni — yǝni Yerusalemni oyup ⱪoyƣin.
2 Kí o sì dó tì í, kí o sì mọ ilé ìṣọ́ tì í, kí o sì mọ odi tì í, kí o sì gbé ogun sí i, kí o sì to òòlù yí i ká.
Andin uni muⱨasirigǝ elip, uningƣa potǝylǝrni ⱪurup, sepilƣa qiⱪidiƣan bir dɵnglük yasap, uning ǝtrapiƣa bargaⱨlarni tikip wǝ sepilni bɵsküqi bazƣanlarni tiklǝp ⱪoyƣin.
3 Kí o sì fi àwo irin kan ṣe ògiri láàrín rẹ̀ àti ìlú yìí, kí o sì kọjú sí i, a ó sì dó tì í, ìwọ yóò sì dó tì í. Èyí yóò jẹ́ àmì fún ilé Israẹli.
Bir tɵmür tahtini elip, uni ɵzüng bilǝn xǝⱨǝrning arisiƣa tiklǝ; yüzüngni uningƣa ⱪaritip tiklǝ; u muⱨasirigǝ elinidu, sǝn ɵzüng uni muⱨasirigǝ alisǝn; bu ixning ɵzi Israil jǝmǝtigǝ bexarǝt bolidu.
4 “Lẹ́yìn èyí, lọ fi ẹ̀gbẹ́ òsì dùbúlẹ̀, kí o sì gbé ẹ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli lé orí ara rẹ. Iye ọjọ́ tí ìwọ bá fi sùn náà ni ìwọ yóò fi ru ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Wǝ sǝn, sol yeningƣa yanpaxlap yatⱪin; Israil jǝmǝtining ⱪǝbiⱨlikini ɵz üstünggǝ ⱪoy; solƣa yanpaxlap ⱪanqǝ kün yatsang, sǝn xunqǝ kün ularning ⱪǝbiⱨlikini kɵtürisǝn.
5 Nítorí mo fi iye ọdún tí wọ́n fi ṣẹ̀ fún ọ gẹ́gẹ́ bí iye ọjọ́ tí ìwọ yóò lò. Nítorí náà, ìwọ yóò ru ẹ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli fún irinwó ọjọ́ ó dín mẹ́wàá.
Mǝn sanga yetix kerǝk bolƣan künlǝrni ularning ⱪǝbiⱨlik ⱪilƣan yilliri boyiqǝ, yǝni üq yüz toⱪsan kün ⱪilip bekitkǝnmǝn; xuning bilǝn sǝn Israil jǝmǝtining ⱪǝbiⱨlikini kɵtürisǝn.
6 “Tí o bá parí èyí, tún fi ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún dùbúlẹ̀ kí o sì ru ẹ̀ṣẹ̀ ilé Juda fún ogójì ọjọ́, nítorí pé ọjọ́ kan ló dúró fún ọdún kan.
Bu künlǝr tügigǝndin keyin, sǝn yǝnǝ ong yanpaxlap yetip, Yǝⱨuda jǝmǝtining ⱪǝbiⱨlikini kɵtürisǝn; sanga ⱪiriⱪ künni bekitkǝnmǝn, ⱨǝrbir kün bir yilni ipadilǝydu.
7 Ìwọ dojúkọ ìgbógunti Jerusalẹmu, na ọwọ́ rẹ sí i, kí o sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ìlú náà.
Wǝ sǝn yüzüngni Yerusalemning muⱨasirisigǝ ⱪaritip, yengingni türgǝn ⱨalda, uni ǝyiblǝp bexarǝt berisǝn;
8 Èmi yóò dè ọ́ ní okùn dé bi pé ìwọ kò ní í le yírapadà láti ìhà ọ̀tún sí ìhà òsì títí tí ọjọ́ ìgbóguntì rẹ yóò fi pé.
wǝ mana, Mǝn üstünggǝ arƣamqilarni salimǝnki, sǝn muⱨasirining künlirini tügǝtmigüqǝ uyan-buyanƣa ⱨeq ɵrülmǝysǝn.
9 “Mú alikama, ọkà bàbà àti barle, erèé àti lẹntili, jéró àti ẹwẹ; fi àwọn nǹkan wọ̀nyí ṣe àkàrà tí ìwọ yóò máa jẹ nígbà tí ìwọ bá dùbúlẹ̀ fún irinwó ọjọ́ ó dín mẹ́wàá.
Wǝ sǝn ɵzünggǝ buƣday, arpa, purqaⱪ, ⱪizil max teriⱪ wǝ ⱪara buƣdaylarni elip bir idix iqigǝ sal; wǝ buningdin ɵzüng üqün tamaⱪ tǝyyarlaysǝn; sǝn buni yanpaxlap yatⱪan künlǝrdǝ, yǝni üq yüz toⱪsan kündǝ yǝysǝn;
10 Wọn òsùwọ̀n ogún ṣékélì oúnjẹ tí ìwọ yóò máa jẹ lójoojúmọ́ kí o sì máa jẹ ẹ́ ní àkókò tí a ti yà sọ́tọ̀.
sǝn yǝydiƣan tamaⱪ bolsa miⱪdari boyiqǝ ⱨǝr küni yigirmǝ xǝkǝldin boluxi kerǝk; sǝn uni bǝlgilǝngǝn waⱪitlarda yǝysǝn;
11 Bákan náà, wọn ìdámẹ́fà omi, kí ìwọ ó sì máa mú ní àkókò tí a yà sọ́tọ̀.
wǝ [ⱨǝr küni] sunimu norma boyiqǝ, yǝni altidin bir ⱨin iqisǝn; [ⱨǝr kündiki] bǝlgilǝngǝn waⱪitlarda iqisǝn.
12 Ìwọ yóò sì jẹ ẹ́ bí àkàrà barle; dín in ní ojú àwọn ènìyàn, ìgbẹ́ ènìyàn ni kí o fi dáná rẹ.”
Sǝn uni arpa kɵmiqi xǝklidǝ ⱪilip yǝysǝn; sǝn uni ularning kɵz aldida insan nijasiti üstidǝ pixurisǝn».
13 Olúwa sọ pé, “Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli yóò jẹ oúnjẹ àìmọ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè tí èmi yóò lé wọn lọ.”
Pǝrwǝrdigar: «Israillar Mǝn ularni ⱨǝydǝp qiⱪiridiƣan ǝllǝr arisida turup xu ⱨaram yolda ɵz nenini ⱨaram yǝydu» — dedi.
14 Nígbà náà ni mo wí pé, “Háà! Kò rí bẹ́ẹ̀ Olúwa Olódùmarè! Láti ìgbà èwe mi di ìsinsin yìí èmi kò tí ì sọ ara mi di aláìmọ́ rí. Èmi kò tí ì jẹ ohun tó kú fúnra rẹ̀ tàbí èyí tí ẹranko búburú fàya pẹ́rẹpẹ̀rẹ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹran àìmọ́ kan kò tí ì wọ ẹnu mi rí.”
Andin mǝn: «I Pǝrwǝrdigar! Mǝn ɵzümni ⱨeqⱪaqan bulƣap ⱪoymidim, wǝ yaxliⱪimdin tartip bügüngǝ ⱪǝdǝr mǝn ɵzi ɵlgǝndin, yaki yirtⱪuqlar boƣup ⱪoyƣan nǝrsidin ⱨeq yemigǝnmǝn; ⱨeqⱪandaⱪ yirginqlik gɵxkǝ aƣzim tegip baⱪmiƣan!» — dedim.
15 Nígbà náà ló wí fún mi pé, “Wò ó, Èmi ó fún ọ ní ìgbẹ́ màlúù dípò ìgbẹ́ ènìyàn. Èmi yóò mú ki ó dín àkàrà rẹ lórí ìgbẹ́ màlúù dípò ìgbẹ́ ènìyàn.”
Wǝ U manga: «Mana, Mǝn sanga insanning nijasitining orniƣa kalining tezikini bǝrdim; sǝn neningni xuning üstidǝ pixurisǝn» — dedi.
16 Ó sì tún sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, èmi yóò dáwọ́ ìpèsè oúnjẹ dúró ní Jerusalẹmu. Ní pípín ni àwọn ènìyàn yóò máa pín oúnjẹ jẹ pẹ̀lú ìfọkànsọ́nà bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni wọn yóò máa mu omi pẹ̀lú ìdààmú,
Wǝ U manga: «I insan oƣli, mana Mǝn Yerusalemda ularƣa yɵlǝnqük bolƣan nanni ⱪurutiwetimǝn; ular nanni taraziƣa selip, uni tǝxwix iqidǝ yǝydu, suni ɵlqǝm bilǝn alaⱪzidilik iqidǝ iqidu;
17 nítorí pé oúnjẹ àti omi yóò wọ́n. Wọn yóò máa wo ara wọn pẹ̀lú ìyanu, èmi yóò sì jẹ́ kí wọ́n ṣọ̀fọ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Qünki nan wǝ su ulardin ⱪalidu; ular bir-birigǝ ⱪarixip dǝⱨxǝt basidu, ɵz ⱪǝbiⱨlikidin ⱪurup ketidu».

< Ezekiel 4 >