< Deuteronomy 14 >

1 Ọmọ Olúwa Ọlọ́run yín ni ẹ̀yin jẹ́: nítorí náà, ẹ má ṣe ya ara yín ní abẹ. Ẹ má ṣe gé irun iwájú orí yín nítorí òkú.
Ie fa ana’ Iehovà Andria­nañahare’ areo, ko mandriadria-tsandriñe ndra mampipeake ty ambonem-pihaino’ areo ty amo vilasio.
2 Nítorí pé ènìyàn mímọ́ ní ẹ jẹ́ fún Olúwa Ọlọ́run yín, nínú gbogbo ènìyàn tí ó wà lórí ilẹ̀ ayé, Ọlọ́run ti yàn yín láti jẹ́ ìṣúra iyebíye rẹ̀.
Amy t’ie ondaty-miavake am’ Iehovà Andrianañahare’o, naho jinobo’ Iehovà h’ondaty an-koroji’e ao boak’ amy ze foko ambone’ ty tane toy.
3 Ẹ má ṣe jẹ ohun ìríra kankan.
Ko kamae’ areo ty raha tiva.
4 Àwọn wọ̀nyí ni ẹranko tí ẹ lè máa jẹ: màlúù, àgùntàn àti ewúrẹ́,
Inao o biby mete kamae’ areoo: ty añombe, ty añondry, naho ty ose,
5 àgbọ̀nrín, èsúró, etu, àgóró, ẹfọ̀n, ìgalà àti àgùntàn igbó.
ty aiàle, tsebý, iakemore, ose-lý, disone, osem-bohitse vaho añondrim-bohitse.
6 Ẹ lè jẹ gbogbo ẹranko tí pátákò ẹsẹ̀ rẹ̀ kì í ṣe méjì tí ó sì tún jẹ àpọ̀jẹ.
Ze biby mivaki-hotro, ie misara-kotro roe amo biby mivazakotao, ie ty ho kamae’ areo.
7 Síbẹ̀síbẹ̀ nínú gbogbo ẹran tí ń jẹ àpọ̀jẹ tí ó sì tún ya pátákò ẹsẹ̀ tí ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ni: ìbákasẹ, ehoro, àti ẹranko tí ó dàbí ehoro tí ń gbé inú àpáta. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n jẹ àpọ̀jẹ, ṣùgbọ́n wọn kò la pátákò ẹsẹ̀, a kà wọ́n sí àìmọ́ fún yín.
Fe tsy ho kamae’ areo ze mpihota haneñe avao, ke vaki-hotroo avao manahake ty rameva, ty bitro naho ty trandrake, fa ndra t’ie mihota haneñe izay, tsy vaki-hotro, aa le faly ama’ areo izay.
8 Ẹlẹ́dẹ̀ jẹ́ àìmọ́; bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ya pátákò ẹsẹ̀, kì í jẹ àpọ̀jẹ, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹran rẹ̀, ẹ kò sì gbọdọ̀ fọwọ́ kan òkú rẹ̀.
le ty lambo, ndra t’ie vaki-hotro, tsy mihota haneñe, le faly ama’ areo. Tsy ho hane’ areo ty hena’e le tsy ho tsapaeñe ty fate’e.
9 Nínú gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ń gbé inú omi, ẹ lè jẹ èyíkéyìí tí ó ní lẹbẹ àti ìpẹ́.
Le inao ty mete kamaeñe amy ze hene raha veloñe an-drano ao: ze rekets’ ela’e naho sisi’e, mete kamae’ areo,
10 Ṣùgbọ́n èyíkéyìí tí kò bá ní lẹbẹ àti ìpẹ́, ẹ má ṣe jẹ ẹ́, nítorí pé àìmọ́ ni wọ́n jẹ́ fún yín.
fe tsy ho kamae’ areo ze tsy aman’ela’e ndra sisi’e, maleotse ama’ areo izay.
11 Ẹ lè jẹ ẹyẹ tí ó bá mọ́.
Mete kamae’ areo ze hene voroñe malio.
12 Ṣùgbọ́n ìwọ̀nyí ní ẹ kò gbọdọ̀ jẹ: idì, igún, àkàlà,
Fa tsy ho kamae’ areo ka iretoy: ty tratràke, ty beivorotse naho ty salale;
13 onírúurú àṣá àti àṣá alátagbà,
ty hitikitike, ty vantio naho ty fañaoke ty amo karaza’eo,
14 onírúurú ẹyẹ ìwò,
le ze hene koàke ty amo karaza’eo;
15 ògòǹgò, òwìwí, pẹ́pẹ́yẹdò àti onírúurú àwòdì,
ty voron-tsatrañe, ty voron-dolo-bori-sofy, ty vorom-potsy naho ze karazan-tsimalaho;
16 onírúurú òwìwí,
ty voron-dolo kede, ty voron-dolom-pikodrìtse naho ty voron-dolo foty
17 òwìwí ọ̀dàn, àkàlà, ìgò,
naho ty voron-dolon-tane maike, ty hondria naho ty voron-dolom-pipao-piañe;
18 àkọ̀, òòdẹ̀, onírúurú ẹyẹ odò mìíràn, atọ́ka àti àdán.
ty sama naho ze karaza-dangoro, ty kotrohake vaho ty kananavy.
19 Àti gbogbo kòkòrò tí ń fò tí wọ́n ń kọ́wọ̀ọ́ rìn jẹ́ aláìmọ́ fun un yín, ẹ má ṣe jẹ wọ́n.
Fonga faly ama’ areo ka ze bibi-kede miropake naho mitiliñe, tsy ho kamaeñe izay.
20 Ṣùgbọ́n ẹ lè jẹ èyíkéyìí ẹ̀dá abìyẹ́ tí ó bá mọ́.
Fe mete kamaeñe ty voroñe malio.
21 Ẹ má ṣe jẹ ohun tí ó ti kú sílẹ̀. Ẹ lè fún àwọn àjèjì tí ń gbé ní èyíkéyìí nínú ìlú yín. Òun lè jẹ ẹ́ tàbí kí ẹ tà á fún àwọn àjèjì. Ṣùgbọ́n ènìyàn mímọ́ fún Olúwa Ọlọ́run yín ni ẹ̀yin jẹ́. Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ewúrẹ́ nínú wàrà ìyá rẹ̀.
Tsy ho kamae’ areo ze nimate bobo­ke; mete atolotse ami’ty renetane mimo­neñe an-drova’o ao ho kamae’e, ke haleta’o ami’ty ambahiny. F’ie ondaty-miavake am’ Iehovà Andrianañahare’o. Vaho tsy hahandroe’o an-drononon-drene’e ty vik’ose.
22 Ẹ rí i dájú pé ẹ̀ ń fi ìdákan nínú mẹ́wàá nínú ìre oko yín lọ́dọọdún pamọ́ sí apá kan.
Toe handivà’o ty fahafolo’ ze hene voka’ o tongise’oo, ze vokare’ o tete’o boa-taoñeo;
23 Ẹ jẹ ìdámẹ́wàá oúnjẹ yín, wáìnì tuntun, òróró, àti àkọ́bí àwọn màlúù yín àti ewúrẹ́ ẹ yín, níwájú Olúwa Ọlọ́run yín, ní ibi tí yóò yàn bí ibùgbé orúkọ rẹ̀. Kí ẹ lè kọ́ bí a ṣé ń bu ọlá fún Olúwa Ọlọ́run yín nígbà gbogbo.
le ho kamae’o añatrefa’ Iehovà Andrianañahare’o, amy toetse ho joboñe’e hampipoha’e i tahina’eiy ty fahafolo’ o mahakama’oo, ty divai’o, ty mena’o vaho ty valohan’ ana’ o añombe’oo naho o mpirai-lia’oo, hioha’o ty hañeveñe am’ Iehovà Andrianañahare’o nainai’e.
24 Bí ibẹ̀ bá jì tí Olúwa Ọlọ́run rẹ sì ti bùkún fún ọ, tí o kò sì le ru àwọn ìdámẹ́wàá rẹ (nítorí pé ibi tí Olúwa yóò yàn láti fi orúkọ rẹ̀ sí jìnnà jù).
Aa naho loho lava i liay, tsy haha­sese i rahay, naho lavitse azo ty toetse ho joboñe’ Iehovà Andrianañahare’o hampi­poha’e i tahina’ey, ie fa nitahia’ Iehovà Andria­nañahare’o
25 Ẹ pààrọ̀ àwọn ìdámẹ́wàá yín sí owó, ẹ mú owó náà lọ sí ibi tí Olúwa yóò yàn.
le itsaloho drala, le vontitiro am-pitàñe ao i dralay, vaho akia mb’amy toetse ho joboñe’ Iehovà Andrianañahare’oy mb’eo;
26 Fi owó náà ra ohunkóhun tí o bá fẹ́, màlúù, àgùntàn, wáìnì, tàbí ọtí líle, tàbí ohunkóhun tí o bá fẹ́. Kí ìwọ àti ìdílé rẹ sì jẹ ẹ́ níwájú Olúwa níbẹ̀ kí ẹ sì máa yọ̀.
kalò ze tea’o amy dralay: he añombe ke añondry, ke divai-vao ke divai-ela, ze satri’ ty tro’o. Le eo ty hikama’o añatrefa’ Iehovà Andria­nañahare’o, vaho mirebeha, ihe naho o keleia’oo.
27 Ẹ má ṣe gbàgbé àwọn Lefi tí ó ń gbé nì ìlú yín, nítorí pé wọn kò ní ìpín kan tàbí ogún kan tí í ṣe tiwọn.
Ko aforintse’o i nte-Levy mpimo­neñe an-drova’oy, ie tsy aman’ anjara ndra lova ama’o.
28 Ní òpin ọdún mẹ́ta mẹ́ta, ẹ̀yin yóò mú gbogbo ìdámẹ́wàá ìre oko àwọn ọdún náà, kí ẹ kó wọn jọ ní ìlú yín.
Ie modo ty taom-paha-telo, le hene hakare’o amy taoñey ty fahafolo’ ty hapeam-boka’o vaho ahajao an-drova’o ao
29 Kí àwọn Lefi (tí kò ní ìpín tàbí ogún tiwọn) àti àwọn àjèjì, àwọn aláìní baba, àti àwọn opó tí ń gbé ìlú yín lè wá, kí wọn sì jẹ kí wọn sì yó, kí Olúwa Ọlọ́run rẹ le è bùkún fún ọ, nínú gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
le homb’eo i nte-Leviy, ie tsy aman’ anjara ndra lova ama’o, naho i renetane mpimoneñe ama’oy naho i bode-raey vaho i vanto­tsey, o añaten-dalambei’oo, le hikama am-para’ t’ie anjañe, soa te hitahy azo t’Iehovà Andrianañahare’o amy ze hene fitoloñam-pità’o.

< Deuteronomy 14 >