< 2 Timothy 4 >

1 Nítorí náà mo pàṣẹ fún ọ níwájú Ọlọ́run, àti Kristi Jesu, ẹni tí yóò ṣe ìdájọ́ alààyè àti òkú, àti nítorí ìfarahàn rẹ̀ àti ìjọba rẹ̀.
ⲁ̅ϯⲉⲣⲙⲉⲑⲣⲉ ⳿ⲙⲡⲉ⳿ⲙⲑⲟ ⳿ⲙⲫϯ ⲛⲉⲙ Ⲡⲭ̅ⲥ̅ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲫⲏⲉⲑⲛⲁϯϩⲁⲡ ⳿ⲉⲛⲏⲉⲧⲟⲛϧ ⲛⲉⲙ ⲛⲏⲉⲑⲙⲱⲟⲩⲧ ⲛⲉⲙ ⲡⲉϥⲟⲩⲟⲛϩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲛⲉⲙ ⲧⲉϥⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ.
2 Wàásù ọ̀rọ̀ náà, ṣe àìsimi ní àkókò tí ó wọ̀, àti àkókò ti kò wọ̀; bá ni wí, ṣe ìtọ́ni, gbani níyànjú pẹ̀lú ìpamọ́ra àti ẹ̀kọ́ gbogbo.
ⲃ̅ϩⲓⲱⲓϣ ⳿ⲙⲡⲓⲥⲁϫⲓ ϣⲱⲡⲓ ϩⲓϫⲱⲟⲩ ⲉⲩⲕⲉⲣⲟⲥ ⲁⲕⲉⲣⲟⲥ ⲥⲟϩⲓ ⲙⲁⲑⲉⲧϩⲏⲧ ⲁⲣⲓⲉⲡⲓⲧⲓⲙⲁⲛ ⳿ⲛ⳿ϧⲣⲏⲓ ϧⲉⲛ ⲙⲉⲧⲣⲉϥⲱⲟⲩ ⳿ⲛϩⲏⲧ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲛⲉⲙ ϯ⳿ⲥⲃⲱ.
3 Nítorí pé ìgbà yóò dé, tí wọn kì yóò lè gba ẹ̀kọ́ tí ó yè kooro, ṣùgbọ́n bí wọ́n ti jẹ́ ẹni tí etí ń rin, wọn ó lọ kó olùkọ́ jọ fún ara wọn nínú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara wọn.
ⲅ̅ⲉϥ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ⲅⲁⲣ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩⲥⲏⲟⲩ ϩⲟⲧⲉ ⳿ⲛⲛⲟⲩϣⲉⲡ ϯ⳿ⲥⲃⲱ ⲉⲑⲟⲩⲟϫ ⲉⲣⲱⲟⲩ ⲁⲗⲗⲁ ⲕⲁⲧⲁ ⲛⲟⲩⲉⲡⲓⲑⲩⲙⲓⲁ ⳿ⲙⲙⲁⲩⲁⲧⲟⲩ ⲉⲩⲥⲱⲕ ⲛⲱⲟⲩ ⳿ⲛϩⲁⲛⲣⲉϥϯ⳿ⲥⲃⲱ ⲉⲩϧⲱϧ ⳿ⲛⲛⲟⲩⲙⲁϣϫ.
4 Wọ́n ó sì yí etí wọn padà kúrò nínú òtítọ́, wọn ó sì yípadà sí ìtàn asán.
ⲇ̅ⲡⲟⲩⲥⲱⲧⲉⲙ ⲙⲉⲛ ⲉⲩ⳿ⲉⲫⲟⲛϩϥ ⲥⲁⲃⲟⲗ ⳿ⲛ⳿ⲑⲙⲏⲓ ⲉⲩⲉⲣⲁⲕⲟⲩ ⲇⲉ ⳿ⲛⲥⲁ ⲛⲓ⳿ϣⲃⲱ.
5 Ṣùgbọ́n máa faradà ìpọ́njú, ṣe iṣẹ́ efangelisti, ṣe iṣẹ́ rẹ láṣepé.
ⲉ̅⳿ⲛⲑⲟⲕ ⲇⲉ ⲁⲣⲓⲛⲩⲙⲫⲓⲛ ϧⲉⲛ ϩⲱⲃ ⲛⲓⲃⲉⲛ ϣⲉⲡ⳿ⲙⲕⲁϩ ⲁⲣⲓϩⲱⲃ ⳿ⲛⲟⲩⲣⲉϥϩⲓϣⲉⲛⲛⲟⲩϥⲓ ⲡⲉⲕϣⲉⲙϣⲓ ϫⲟⲕϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ.
6 Nítorí à ń fi mi rú ẹbọ nísinsin yìí, àtilọ mi sì súnmọ́ etílé.
ⲋ̅⳿ⲁⲛⲟⲕ ⲅⲁⲣ ϩⲏⲇⲏ ⲥⲉⲛⲁⲟⲩⲟⲑⲃⲉⲧ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲡⲥⲏⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲁⲃⲱⲗ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲁϥϧⲱⲛⲧ.
7 Èmi ti ja ìjà rere, èmi tí parí iré-ìje mi, èmi ti pa ìgbàgbọ́ mọ́.
ⲍ̅ⲡⲓⲁⲅⲱⲛ ⲉⲑⲛⲁⲛⲉϥ ⲁⲓⲉⲣⲁⲅⲱⲛⲓⲍⲉⲥⲑⲉ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⲡⲓ⳿ⲇⲣⲟⲙⲟⲥ ⲁⲓϫⲟⲕϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲡⲓⲛⲁϩϯ ⲁⲓⲁⲣⲉϩ ⳿ⲉⲣⲟϥ.
8 Láti ìsinsin yìí lọ a fi adé òdodo lélẹ̀ fún mi, tí Olúwa onídàájọ́ òdodo, yóò fífún mi ni ọjọ́ náà kì í sì í ṣe kìkì èmi nìkan ṣùgbọ́n pẹ̀lú fún gbogbo àwọn tí ó ti fẹ́ ìfarahàn rẹ̀.
ⲏ̅ⲗⲟⲓⲡⲟⲛ ⳿ϥⲭⲏ ⲛⲏⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓ⳿ⲭⲗⲟⲙ ⳿ⲛⲧⲉ ϯⲇⲓⲕⲉⲟⲥⲩⲛⲏ ⲫⲏⲉⲧⲉ Ⲡ⳪ ⲛⲁⲧⲏⲓϥ ⲛⲏⲓ ϧⲉⲛ ⲡⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ⲉⲧⲉ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⲡⲓⲣⲉϥϯϩⲁⲡ ⳿ⲙⲙⲏⲓ ⲟⲩ ⲙⲟⲛⲟⲛ ⲇⲉ ⲛⲏⲓ ⳿ⲙⲙⲁⲩⲁⲧ ⲁⲗⲗⲁ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲟⲛ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲉⲧⲁⲩⲙⲉⲛⲣⲉ ⲡⲉϥⲟⲩⲟⲛϩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ.
9 Sa ipá rẹ láti tètè tọ̀ mí wá.
ⲑ̅ⲓⲏⲥ ⳿ⲛⲧⲟⲧⲕ ⳿ⲉ⳿ⲓ ϩⲁⲣⲟⲓ ⳿ⲛⲭⲱⲗⲉⲙ.
10 Nítorí Dema ti kọ̀ mí sílẹ̀, nítorí ó ń fẹ́ ayé yìí, ó sì lọ sí Tẹsalonika; Kreskeni sí Galatia, Titu sí Dalimatia. (aiōn g165)
ⲓ̅ⲇⲏⲙⲁⲥ ⲅⲁⲣ ⲁϥⲭⲁⲧ ⳿ⲛⲥⲱϥ ⳿ⲉⲁϥⲙⲉⲛⲣⲉ ⲡⲁⲓⲉⲛⲉϩ ⳿ⲛⲧⲉ ϯⲛⲟⲩ ⲁϥϣⲉ ⲛⲁϥ ⳿ⲉⲑⲉⲥⲥⲁⲗⲟⲛⲓⲕⲓⲁ ⳿ⲕⲣⲓⲥⲕⲏⲥ ⳿ⲉϯⲅⲁⲗⲁⲧⲓⲁ ⲧⲓⲧⲟⲥ ⳿ⲉⲇⲁⲗⲙⲁⲧⲓⲁ. (aiōn g165)
11 Luku nìkan ni ó wà pẹ̀lú mi, mú Marku wá pẹ̀lú rẹ: nítorí ó wúlò fún mi fún iṣẹ́ ìránṣẹ́.
ⲓ̅ⲁ̅ⲗⲟⲩⲕⲁⲥ ⳿ⲙⲙⲁⲩⲁⲧϥ ⲉⲑⲛⲉⲙⲏⲓ ⲙⲁⲣⲕⲟⲥ ⲙⲁⲗⲟϥ ⲁⲛⲓⲧϥ ⲛⲉⲙⲁⲕ ⳿ϥⲉⲣϣⲁⲩ ⲅⲁⲣ ⲛⲏⲓ ⲉⲩⲇⲓⲁⲕⲟⲛⲓⲁ.
12 Mo rán Tikiku ní iṣẹ́ lọ sí Efesu.
ⲓ̅ⲃ̅ⲧⲩⲭⲓⲕⲟⲥ ⲇⲉ ⲁⲓⲟⲩⲟⲣⲡϥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲉⲫⲉⲥⲟⲥ.
13 Aṣọ òtútù tí mo fi sílẹ̀ ní Troasi lọ́dọ̀ Karpu, nígbà tí ìwọ bá ń bọ̀ mú un wa, àti àwọn ìwé, pẹ̀lúpẹ̀lú àwọn ìwé-awọ.
ⲓ̅ⲅ̅ϯⲫⲩⲗⲟⲛⲏⲉⲧⲁⲓⲥⲟϫⲡⲥ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲣⲱⲁⲥ ϧⲁⲧⲉⲛ ⲕⲁⲣⲡⲱ ⲁⲛⲓⲧⲥ ⲉⲕⲛⲏⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲕⲉϫⲱⲙ ⲙⲁⲗⲓⲥⲧⲁ ⲛⲓⲙⲉⲛ⳿ⲃⲣⲁⲛⲁ.
14 Aleksanderu alágbẹ̀dẹ bàbà ṣe mi ni ibi púpọ̀: Olúwa yóò san án fún un gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀.
ⲓ̅ⲇ̅ⲁⲗⲉⲝⲁⲛⲇⲣⲟⲥ ⲡⲓⲃⲉⲥⲛⲏⲧ ⲁϥⲉⲣⲟⲩⲙⲏϣ ⳿ⲙⲡⲉⲧϩⲱⲟⲩ ⲛⲏⲓ ⲉⲣⲉ Ⲡ⳪ ϯϣⲉⲃⲓⲱ ⲛⲁϥ ⲕⲁⲧⲁ ⲛⲉϥ⳿ϩⲃⲏⲟⲩ⳿ⲓ.
15 Lọ́dọ̀ ẹni tí kí ìwọ máa ṣọ́ra pẹ̀lú, nítorí tí ó kọ ojú ìjà sí ìwàásù wa púpọ̀.
ⲓ̅ⲉ̅ⲫⲁⲓ ⲉⲧⲉ ⳿ⲛⲑⲟⲕ ϩⲱⲕ ⲁⲣⲉϩ ⳿ⲉⲣⲟⲕ ⲥⲁⲃⲟⲗ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⲁϥϯ ⲅⲁⲣ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉ⳿ϩⲣⲉⲛ ⲛⲁⲥⲁϫⲓ ⳿ⲉⲙⲁϣⲱ.
16 Ní àkọ́kọ́ jẹ́ ẹjọ́ mi, kò sí ẹni tí ó ba mi gba ẹjọ́ rò ṣùgbọ́n gbogbo ènìyàn ni o kọ̀ mi sílẹ̀, àdúrà mi ni kí a má ṣe kà á sí wọn lọ́rùn.
ⲓ̅ⲋ̅ϧⲉⲛ ⲧⲁϩⲟⲩⲓϯ ⳿ⲛⲁⲡⲟⲗⲟⲅⲓⲁ ⳿ⲙⲡⲉϥⲭⲁ ⳿ϩⲗⲓ ⳿ⲉ⳿ⲓ ϩⲁⲣⲟⲓ ⲁⲗⲗⲁ ⲁⲩⲭⲁⲧ ⳿ⲛⲥⲱⲟⲩ ⲧⲏⲣⲟⲩ ⳿ⲛⲛⲟⲩⲱⲡ ⲛⲉⲙⲱⲟⲩ.
17 Ṣùgbọ́n Olúwa gba ẹjọ́ mi rò, ó sì fún mi lágbára; pé nípasẹ̀ mi kí a lè wàásù náà ní àwàjálẹ̀, àti pé kí gbogbo àwọn aláìkọlà lè gbọ́; a sì gbà mí kúrò lẹ́nu kìnnìún náà.
ⲓ̅ⲍ̅Ⲡ⳪ ⲇⲉ ⲁϥⲟϩⲓ ⳿ⲉⲣⲁⲧϥ ⲛⲉⲙⲏⲓ ⲁϥ ϯϫⲟⲙ ⲛⲏⲓ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲧⲟⲧ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓϩⲓⲱⲓϣ ϫⲱⲕ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲟⲩⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓⲉⲑⲛⲟⲥ ⲧⲏⲣⲟⲩ ϫⲉ ⲁⲓⲛⲟϩⲉⲙ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲣⲱϥ ⲛⲟⲩⲙⲟⲩ⳿ⲓ.
18 Olúwa yóò yọ mí kúrò nínú iṣẹ́ búburú gbogbo, yóò sì mu mí dé inú ìjọba ọ̀run. Ẹni ti ògo wà fún láé àti láéláé. Àmín. (aiōn g165)
ⲓ̅ⲏ̅ⲉϥ⳿ⲉⲧⲟⲩϫⲟⲓ ⳿ⲛϫⲉ Ⲡ⳪ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲁ ϩⲱⲃ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲉⲧϩⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲉϥ⳿ⲉⲛⲁϩⲙⲉⲧ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲧⲉϥⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲧⲫⲉ ⲫⲁⲓ ⲉⲧⲉ ⲫⲱϥ ⲡⲉ ⲡⲓⲱⲟⲩ ϣⲁ ⲉⲛⲉϩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓⲉⲛⲉϩ ⲁⲙⲏⲛ. (aiōn g165)
19 Kí Priska àti Akuila, àti ilé Onesiforu.
ⲓ̅ⲑ̅ϣⲓⲛⲓ ⳿ⲉ⳿ⲡⲣⲓⲥⲕⲩⲗⲗⲁ ⲛⲉⲙ ⲁⲕⲩⲗⲗⲁ ⲛⲉⲙ ⳿ⲡⲏⲓ ⳿ⲛⲟⲛⲏⲥⲓⲫⲟⲣⲟⲥ.
20 Erastu wà ní Kọrinti: ṣùgbọ́n mo fi Tirofimu sílẹ̀ ni Miletu nínú àìsàn.
ⲕ̅ⲉⲣⲁⲥⲧⲟⲥ ⲁϥⲟϩⲓ ϧⲉⲛ ⲕⲟⲣⲓⲛⲑⲟⲥ ⳿ⲧⲣⲟⲫⲏ ⲙⲟⲥ ⲇⲉ ⲁⲓⲥⲟϫⲡϥ ϧⲉⲛ ⲙⲉⲗⲓⲧⲟⲥ ⲉϥϣⲱⲛⲓ.
21 Sa ipá rẹ láti tètè wá ṣáájú ìgbà òtútù. Eubulu kí ọ, àti Pudeni, àti Linu, Klaudia, àti gbogbo àwọn arákùnrin.
ⲕ̅ⲁ̅ⲓⲏⲥ ⳿ⲙⲙⲟⲕ ⳿ⲉ⳿ⲓ ϧⲁϫⲉⲛ ϯ⳿ⲫⲣⲱ ⳿ϥϣⲓⲛⲓ ⳿ⲉⲣⲟⲕ ⳿ⲛϫⲉ ⲉⲩⲃⲟⲩⲗⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲡⲟⲩⲇⲏⲥ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲗⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⳿ⲕⲗⲁⲩⲇⲓⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲛⲓ⳿ⲥⲛⲏⲟⲩ ⲧⲏⲣⲟⲩ.
22 Kí Olúwa wà pẹ̀lú ẹ̀mí rẹ kí oore-ọ̀fẹ́ wà pẹ̀lú yín.
ⲕ̅ⲃ̅Ⲡ⳪ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ Ⲡⲭ̅ⲥ̅ ⲛⲉⲙ ⲡⲉⲕⲡ͞ⲛⲁ̅ ⳿ⲛ⳿ϩⲙⲟⲧ ⲛⲉⲙⲱⲧⲉⲛ ⳿ⲡⲣⲟⲥ ⲧⲓⲙⲟⲑ ⲃ̅ ⲁⲩ⳿ⲥϧⲏⲧⲥ ϧⲉⲛ ⲗⲁⲟⲇⲓⲕⲓⲁ ϯⲙⲉⲧⲣⲟⲡⲟⲗⲓⲥ

< 2 Timothy 4 >