< 1 Samuel 1 >

1 Ọkùnrin kan wà, láti Ramataimu-Sofimu, láti ìlú olókè Efraimu, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Elkana, ọmọ Jerohamu, ọmọ Elihu, ọmọ Tohu, ọmọ Sufu, ará Efrata.
Na rĩrĩ, nĩ kwarĩ na mũndũ ũmwe wa kuuma Ramathaimu, Mũzofimu kuuma bũrũri ũrĩa ũrĩ irĩma wa Efiraimu, nake eetagwo Elikana mũrũ wa Jerohamu, mũrũ wa Elihu, mũrũ wa Tohu, mũrũ wa Zufu, Mũefiraimu.
2 Ó sì ní ìyàwó méjì, orúkọ wọn ni Hana àti Penina: Penina ní ọmọ, ṣùgbọ́n Hana kò ní.
Aarĩ na atumia eerĩ; ũmwe eetagwo Hana na ũrĩa ũngĩ eetagwo Penina. Penina aarĩ na ciana, no Hana ndaarĩ na ciana.
3 Ní ọdọọdún, ọkùnrin yìí máa ń gòkè láti ìlú rẹ̀ láti lọ sìn àti láti ṣe ìrúbọ sí Olúwa àwọn ọmọ-ogun jùlọ ní Ṣilo, níbi tí àwọn ọmọkùnrin Eli méjèèjì, Hofini àti Finehasi ti jẹ́ àlùfáà Olúwa.
Mwaka o mwaka mũndũ ũcio nĩambataga kuuma itũũra rĩake agathiĩ Shilo kũhooya na kũrutĩra Jehova Mwene-Hinya-Wothe igongona. Shilo nĩkuo Hofini na Finehasi, ariũ eerĩ a Eli, maarĩ athĩnjĩri-Ngai a Jehova.
4 Nígbàkígbà tí ó bá kan Elkana láti ṣe ìrúbọ, òun yóò bù lára ẹran fún aya rẹ̀ Penina àti fún gbogbo àwọn ọmọ ọkùnrin àti obìnrin.
Rĩrĩa rĩothe mũthenya wa Elikana wakinyaga wa kũruta igongona-rĩ, nĩagayagĩra mũtumia wake Penina nyama, hamwe na aanake ake othe o na airĩtu.
5 Ṣùgbọ́n ó máa ń pín ìlọ́po fun Hana nítorí pé ó fẹ́ràn rẹ̀ àti pé Olúwa ti sé e nínú.
No nĩaheaga Hana rũgai maita meerĩ, tondũ nĩamwendete, nowe Jehova nĩamũhingĩte nda.
6 Nítorí pé Olúwa ti sé e nínú, orogún rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí ní fín níràn láti lè mú kí ó bínú.
Na tondũ Jehova nĩamũhingĩte nda-rĩ, mũiruwe nĩaikaraga akĩmũthirĩkagia nĩguo amũngʼũrĩkie.
7 Eléyìí sì máa ń ṣẹlẹ̀ ní ọdọọdún. Nígbàkígbà tí Hana bá gòkè lọ sí ilé Olúwa, orogún rẹ̀ a máa fín níràn títí tí yóò fi máa sọkún tí kò sì ní lè jẹun.
Naguo ũndũ ũcio ũgĩthiĩ na mbere mwaka o mwaka. Rĩrĩa rĩothe Hana aambataga athiĩ nyũmba ya Jehova-rĩ, mũiruwe nĩamũthirĩkagia nginya akarĩra, akaaga kũrĩa irio.
8 Elkana ọkọ rẹ̀ yóò sọ fún un pé, “Hana èéṣe tí ìwọ fi ń sọkún? Èéṣe tí ìwọ kò fi jẹun? Èéṣe tí ìwọ fi ń ba ọkàn jẹ́? Èmi kò ha ju ọmọ mẹ́wàá lọ fún ọ bí?”
Nake Elikana mũthuuriwe akamũũria atĩrĩ, “Hana, ũrarĩra nĩkĩ? Ũraaga kũrĩa nĩkĩ? Ũkuĩte ngoro nĩkĩ? Githĩ niĩ ndikĩrĩte ihĩĩ ikũmi harĩwe?”
9 Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n ti jẹ, tí wọ́n tún mu tán ní Ṣilo, Hana dìde wá síwájú Olúwa. Nígbà náà, Eli àlùfáà wà lórí àga ní ẹ̀gbẹ́ ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa ní ibi tí ó máa ń jókòó.
Hĩndĩ ĩmwe maarĩkia kũrĩa na kũnyua marĩ kũu Shilo-rĩ, Hana agĩũkĩra. Na rĩrĩ, Eli, mũthĩnjĩri-Ngai, aikarĩire gĩtĩ itoonyero rĩa hekarũ ya Jehova.
10 Pẹ̀lú ẹ̀dùn ọkàn Hana sọkún gidigidi, ó sì gbàdúrà sí Olúwa.
Hana akĩrĩra mũno na akĩhooya Jehova, arĩ na ruo rwa ngoro.
11 Ó sì jẹ́ ẹ̀jẹ́ wí pé, “Olúwa àwọn ọmọ-ogun, jùlọ tí ìwọ bá le bojú wo ìránṣẹ́bìnrin rẹ kí ìwọ sì rántí rẹ̀, tí ìwọ kò sì gbàgbé ìránṣẹ́ rẹ ṣùgbọ́n tí ìwọ yóò fún un ní ọmọkùnrin, nígbà náà èmi yóò sì fi fún Olúwa ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀ a kì yóò sì fi abẹ kàn án ní orí.”
Nake akĩĩhĩta mwĩhĩtwa, akiuga atĩrĩ, “Wee Jehova Mwene-Hinya-Wothe, ũngĩĩtĩkĩra kũrora thĩĩna wa ndungata yaku na ũndirikane, na ndũkariganĩrwo nĩ ndungata yaku, no ũmĩhe mwana wa kahĩĩ-rĩ, hĩndĩ ĩyo na niĩ nĩngamũheana kũrĩ Jehova matukũ mothe ma muoyo wake, na gũtirĩ hĩndĩ rwenji rũkaahutia mũtwe wake o na rĩ.”
12 Bí ó sì ṣe ń gbàdúrà sí Olúwa, Eli sì kíyèsi ẹnu rẹ̀.
Na rĩrĩa aathiiaga na mbere kũhooya Jehova, Eli akĩmũbara kanua.
13 Hana ń gbàdúrà láti inú ọkàn rẹ̀, ṣùgbọ́n ètè rẹ̀ ni ó ń mì, a kò gbọ́ ohùn rẹ̀. Eli rò wí pé ó ti mu ọtí yó.
Hana aahooyaga na ngoro yake, nacio iromo ciake nĩciainainaga, no mũgambo wake ndwaiguĩkaga. Eli agĩĩciiria atĩ nĩ kũrĩĩo arĩĩtwo,
14 Eli sì wí fún un pé, “Yóò ti pẹ́ fún ọ tó tí ìwọ yóò máa yó? Mú ọtí wáìnì rẹ̀ kúrò.”
akĩmũũria atĩrĩ, “Nĩ nginya rĩ ũgũikara ũrĩ mũrĩĩu? Eheria ndibei ĩyo yaku.”
15 Hana dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́, Olúwa mi, èmi ni obìnrin oníròbìnújẹ́. Èmi kò mu ọtí wáìnì tàbí ọtí líle; èmi ń tú ọkàn mi jáde sí Olúwa ni.
Hana akĩmũcookeria, akiuga atĩrĩ, “Tiguo mwathi wakwa, niĩ ndĩ mũndũ-wa-nja ũthĩĩnĩkĩte mũno. Ndinyuĩte ndibei kana njoohi; no nĩ ngoro yakwa ndĩraitũrũrĩra Jehova.
16 Má ṣe mú ìránṣẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ bí obìnrin búburú. Èmi ti ń gbàdúrà níhìn-ín nínú ìrora ọkàn àti ìbànújẹ́ mi.”
Tiga kuona ndungata yaku ta ĩrĩ mũndũ-wa-nja mwaganu; ngoretwo gũkũ ngĩhooya ndĩ na ruo rũingĩ o na kĩeha.”
17 Eli dáhùn pé, “Máa lọ ní àlàáfíà, kí Ọlọ́run Israẹli fi ohun tí ìwọ ti béèrè ní ọwọ́ rẹ̀ fún ọ.”
Eli akĩmũcookeria atĩrĩ, “Thiĩ na thayũ, na Ngai wa Isiraeli aroĩtĩkĩra gũkũhe kĩrĩa ũmũhooete.”
18 Ó wí pé, “Kí ìránṣẹ́bìnrin rẹ rí oore-ọ̀fẹ́ lójú rẹ.” Bẹ́ẹ̀ ni obìnrin náà bá tirẹ̀ lọ, ó sì jẹun, kò sì fa ojú ro mọ́.
Nake akiuga atĩrĩ, “Ndungata yaku ĩroĩtĩkĩrĩka maitho-inĩ maku.” Nake Hana agĩthiĩ na akĩrĩa irio, na ndaacookire gũtuka gĩthiithi.
19 Wọ́n sì dìde ni kùtùkùtù òwúrọ̀, wọn wólẹ̀ sìn níwájú Olúwa, wọn padà wa sí ilé wọn ni Rama: Elkana si mọ Hana aya rẹ̀: Olúwa sì rántí rẹ̀.
Magĩũkĩra mũthenya ũyũ ũngĩ rũciinĩ tene, makĩhooya marĩ mbere ya Jehova, na magĩcooka magĩthiĩ kwao mũciĩ kũu Rama. Elikana agĩkoma na Hana mũtumia wake, nake Jehova akĩmũririkana.
20 Ó sì ṣe, nígbà tí ọjọ́ rẹ̀ pé, lẹ́yìn ìgbà tí Hana lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan, ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Samuẹli, pé, “Nítorí tí mo béèrè rẹ̀ lọ́wọ́ Olúwa.”
Nĩ ũndũ ũcio ihinda rĩgĩkinya Hana akĩgĩa nda na agĩciara kahĩĩ. Agĩgatua Samũeli, akiuga atĩrĩ, “Nĩgũkorwo nĩ kũhooya ndakahooire harĩ Jehova.”
21 Ọkùnrin náà Elkana, àti gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀, gòkè lọ láti rú ẹbọ ọdún sí Olúwa, àti láti sán ẹ̀jẹ́ rẹ̀.
Rĩrĩa mũndũ ũcio wetagwo Elikana aambatire hamwe na nyũmba yake yothe kũrutĩra Jehova igongona rĩa mwaka o mwaka na akahingie mwĩhĩtwa wake-rĩ,
22 Ṣùgbọ́n Hana kò gòkè lọ; nítorí tí ó sọ fún ọkọ rẹ̀ pé, “Ó di ìgbà tí mo bá gba ọmú lẹ́nu ọmọ náà, nígbà náà ni èmi yóò mú un lọ, kí òun lè fi ara hàn níwájú Olúwa, kí ó sí máa gbé ibẹ̀ títí láé.”
Hana ndaathiire. Eerire mũthuuriwe atĩrĩ, “Kahĩĩ gaka gaatiga kuonga-rĩ, nĩngagatwara na ndĩkaneane kũrĩ Jehova, na gagaatũũraga kũu hĩndĩ ciothe.”
23 Elkana ọkọ rẹ̀ sì wí fún un pé, “Ṣe èyí tí ó tọ́ lójú rẹ. Dúró títí ìwọ yóò fi gba ọmú lẹ́nu rẹ̀; ṣùgbọ́n kí Olúwa sá à mú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ.” Bẹ́ẹ̀ ni obìnrin náà sì jókòó, ó sì fi ọmú fún ọmọ rẹ̀ títí ó fi gbà á lẹ́nu rẹ̀.
Mũthuuriwe Elikana akĩmwĩra atĩrĩ, “Ĩka o ũrĩa ũkuona kwagĩrĩire. Ikara gũkũ o nginya rĩrĩa gagaatiga kuonga; we Jehova arotũma kiugo gĩake kĩhinge.” Nĩ ũndũ ũcio mũndũ-wa-nja ũcio agĩikara mũciĩ na agĩkongithia nginya rĩrĩa aagatigithirie kuonga.
24 Nígbà tí ó sì gba ọmú lẹ́nu rẹ̀, ó sì mú un gòkè lọ pẹ̀lú ara rẹ̀. Pẹ̀lú ẹgbọrọ màlúù mẹ́ta, àti ìyẹ̀fun efa kan, àti ìgò ọtí wáìnì kan, ó sì mú un wá sí ilé Olúwa ní Ṣilo: ọmọ náà sì wà ní ọmọdé.
Gaatiga kuonga, Hana akĩoya kahĩĩ kau o karĩ kanini, hamwe na ndegwa ya mĩaka ĩtatũ, na eba ĩmwe ya mũtu, na gĩtete kĩa ndibei agĩgatwara nyũmba ya Jehova kũu Shilo.
25 Wọ́n pa ẹgbọrọ màlúù, wọ́n sì mú ọmọ náà tọ Eli wá.
Maarĩkia gũthĩnja ndegwa-rĩ, magĩtwara kahĩĩ kau kũrĩ Eli,
26 Hana sì wí pé, “Olúwa mi, bí ọkàn rẹ ti wà láààyè, Olúwa mi, èmi ni obìnrin náà tí ó dúró lẹ́bàá ọ̀dọ̀ rẹ níhìn-ín tí ń tọrọ lọ́dọ̀ Olúwa.
Nake Hana akĩmwĩra atĩrĩ, “Ti-itherũ o ta ũrĩa wee mwathi wakwa ũtũũraga muoyo-rĩ, nĩ niĩ mũndũ-wa-nja ũrĩa warũgamĩte haha hakuhĩ nawe akĩhooya Jehova.
27 Ọmọ yìí ni mo ń tọrọ; Olúwa sì fi ìdáhùn ìbéèrè tí mo béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀ fún mi.
Ndahooire heo kahĩĩ gaka, nake Jehova nĩetĩkĩrĩte kũũhe kĩrĩa ndamũhooire.
28 Nítorí náà pẹ̀lú, èmi fi í fún Olúwa; ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀: nítorí tí mo ti béèrè rẹ̀ fún Olúwa.” Wọn si wólẹ̀ sin Olúwa níbẹ̀.
Tondũ ũcio o na niĩ nĩndakaamũrĩra Jehova. Matukũ mothe marĩa gegũtũũra muoyo-rĩ, gegũtũũra kaamũrĩirwo Jehova.” Nake akĩhooya Jehova arĩ o hau.

< 1 Samuel 1 >