< 1 Samuel 2 >

1 Hana sì gbàdúrà pé, “Ọkàn mi yọ̀ sí Olúwa; ìwo agbára mi ni a sì gbé sókè sí Olúwa. Ẹnu mi sì gbòòrò lórí àwọn ọ̀tá mi, nítorí ti èmi yọ̀ ni ìgbàlà rẹ̀.
Ningĩ Hana akĩhooya, akiuga atĩrĩ:
2 “Kò sí ẹni tí ó mọ́ bi Olúwa; kò sí ẹlòmíràn bí kò ṣe ìwọ; kò sì sí àpáta bi Ọlọ́run wa.
“Gũtirĩ mũndũ o na ũ mũtheru ta Jehova;
3 “Má ṣe halẹ̀; má ṣe jẹ́ kí ìgbéraga ti ẹnu yín jáde nítorí pé Ọlọ́run olùmọ̀ ni Olúwa, láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ wá ni a ti ń wọn ìwà.
“Mũtigacooke kwaria na mwĩĩkĩrĩro ũguo
4 “Ọ̀run àwọn alágbára ti ṣẹ́, àwọn tí ó ṣe aláìlera ni a fi agbára dì ní àmùrè.
“Mota ma njamba cia ita nĩmoinangĩku,
5 Àwọn tí ó yọ̀ fún oúnjẹ ti fi ara wọn ṣe alágbàṣe, àwọn tí ebi ń pa kò sì ṣe aláìní. Tó bẹ́ẹ̀ tí àgàn fi bí méje. Ẹni tí ó bímọ púpọ̀ sì di aláìlágbára.
Arĩa maarĩ ahũũnu meyandĩkithagia nĩguo mone irio,
6 “Olúwa pa ó sì sọ di ààyè; ó mú sọ̀kalẹ̀ lọ sí isà òkú, ó sì gbé dìde. (Sheol h7585)
“Jehova nĩwe ũrehaga gĩkuũ, na nĩwe ũtũũragia muoyo; (Sheol h7585)
7 Olúwa sọ di tálákà; ó sì sọ di ọlọ́rọ̀; ó rẹ̀ sílẹ̀, ó sì gbé sókè.
Jehova nĩwe ũtũmaga andũ mathĩĩne na arĩa angĩ matonge;
8 Ó gbé tálákà sókè láti inú erùpẹ̀ wá, ó gbé alágbe sókè láti orí òkìtì eérú wá, láti mú wọn jókòó pẹ̀lú àwọn ọmọ-aládé, láti mu wọn jogún ìtẹ́ ògo, “Nítorí pé ọ̀wọ́n ayé ti Olúwa ni, ó sì ti gbé ayé ka orí wọn.
Ooyaga mũthĩĩni akamũruta rũkũngũ-inĩ,
9 Yóò pa ẹsẹ̀ àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ mọ́, àwọn ènìyàn búburú ni yóò dákẹ́ ní òkùnkùn. “Nípa agbára kò sí ọkùnrin tí yóò borí.
Nĩakamenyerera makinya ma andũ ake arĩa atheru,
10 A ó fọ́ àwọn ọ̀tá Olúwa túútúú; láti ọ̀run wá ni yóò sán àrá sí wọn; Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ òpin ayé. “Yóò fi agbára fún ọba rẹ̀, yóò si gbé ìwo ẹni àmì òróró rẹ̀ sókè.”
arĩa makararagia Jehova nĩmagathuthwo.
11 Elkana sì lọ sí Rama, sí ilé rẹ̀, ọmọ náà sì ń ṣe ìránṣẹ́ fún Olúwa níwájú Eli àlùfáà.
Nake Elikana akĩinũka mũciĩ gwake Rama, no kahĩĩ kau gagĩtungatĩra Jehova karĩ harĩ Eli ũcio mũthĩnjĩri-Ngai.
12 Àwọn ọmọ Eli sì jẹ́ ọmọ Beliali; wọn kò mọ Olúwa.
Na rĩrĩ, ariũ a Eli maarĩ andũ aaganu; matiatĩĩte Jehova.
13 Iṣẹ́ àwọn àlùfáà pẹ̀lú àwọn ènìyàn ni pé nígbà tí ẹnìkan bá ṣe ìrúbọ, ìránṣẹ́ àlùfáà á dé, nígbà tí ẹran náà bá ń hó lórí iná, pẹ̀lú ọ̀pá-ẹran náà oníga mẹ́ta ní ọwọ́ rẹ̀.
Na rĩrĩ, warĩ mũtugo wa athĩnjĩri-Ngai harĩ andũ, atĩ rĩrĩa mũndũ o wothe aruta igongona, na rĩrĩa nyama ikĩrugwo, ndungata ya mũthĩnjĩri-Ngai yokaga na njibe ya mĩtheece ĩtatũ ĩrĩ guoko-inĩ.
14 Òun a sì fi gún inú apẹ, tàbí àgé tàbí ọpọ́n, tàbí ìkòkò, gbogbo èyí tí ọ̀pá-ẹran oníga náà bá mú wá sí òkè, àlùfáà á mú un fún ara rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń ṣe sí gbogbo Israẹli tí ó wá sí ibẹ̀ ní Ṣilo.
Yaikagia njibe ĩyo nyũngũ-inĩ ya kĩgera, kana thaburia-inĩ, kana gĩtengʼũ-inĩ, kana nyũngũ-inĩ ya rĩũmba, nake mũthĩnjĩri-Ngai akeyoera o kĩrĩa gĩothe njibe ĩngĩarutire. Ũguo nĩguo meekaga andũ othe a Isiraeli arĩa mookaga Shilo.
15 Pẹ̀lú, kí wọn tó sun ọ̀rá náà, ìránṣẹ́ àlùfáà á dé, á sì wí fún ọkùnrin tí ó ń ṣe ìrúbọ pé, “Fi ẹran fún mi láti sun fún àlùfáà; nítorí tí kì yóò gba ẹran sísè lọ́wọ́ rẹ, bí kò ṣe tútù.”
Na o na mbere ya maguta gũcinwo-rĩ, ndungata ya mũthĩnjĩri-Ngai nĩyokaga na ĩkeera mũndũ ũrĩa ũraruta igongona atĩrĩ, “He mũthĩnjĩri-Ngai nyama imwe ahĩĩhie; ndegwĩtĩkĩra nyama nduge kuuma kũrĩ we, tiga o nyama njĩthĩ.”
16 Bí ọkùnrin náà bá sì wí fún un pé, “Jẹ́ kí wọn ó sun ọ̀rá náà nísinsin yìí, kí o sì mú iyekíye tí ọkàn rẹ̀ bá fẹ́,” nígbà náà ni yóò dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́, ṣùgbọ́n kí ìwọ ó fi í fún mi nísinsin yìí, bí kó ṣe bẹ́ẹ̀, èmi ó fi agbára gbà á.”
Mũndũ angĩamwĩrire atĩrĩ, “Reke maguta mambe macinwo, ũcooke woe kĩrĩa gĩothe ũkwenda,” ndungata yacookagia atĩrĩ, “Aca, nengera o ro rĩu; kwaga ũguo, ndĩmĩoe na hinya.”
17 Ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì tóbi gidigidi níwájú Olúwa: nítorí tí àwọn ènìyàn kórìíra ẹbọ Olúwa.
Wĩhia ũcio wa aanake a Eli warĩ mũnene mũno maitho-inĩ ma Jehova, nĩgũkorwo nĩmanyararaga magongona marĩa andũ maarutagĩra Jehova.
18 Ṣùgbọ́n Samuẹli ń ṣe ìránṣẹ́ níwájú Olúwa, ọmọdé, ti a wọ̀ ní efodu ọ̀gbọ̀.
Nowe Samũeli aatungataga mbere ya Jehova arĩ o mwana mũnini, ehumbĩte ebodi ya gatani.
19 Pẹ̀lúpẹ̀lú, ìyá rẹ̀ máa ń dá aṣọ ìlekè péńpé fún un, a sì máa mú wá fún un lọ́dọọdún, nígbà tí ó bá bá ọkọ rẹ̀ gòkè wá láti ṣe ìrúbọ ọdún.
O mwaka nyina nĩamũtumagĩra gakanjũ, akamũtwarĩra rĩrĩa megũthiĩ na mũthuuriwe kũruta igongona rĩa mwaka o mwaka.
20 Eli súre fún Elkana àti aya rẹ̀ pé, “Kí Olúwa fún ọ ní irú-ọmọ láti ara obìnrin yìí wá, nítorí ẹ̀bùn tí ó béèrè tí ó sì tún fún Olúwa.” Wọ́n sì lọ sí ilé wọn.
Eli nĩarathimaga Elikana na mũtumia wake, akoiga atĩrĩ, “Jehova arokũhe ciana na mũndũ-wa-nja ũyũ icooke ithenya rĩa mwana ũyũ aahooete, na agĩcooka kũmũheana harĩ Jehova.” Nao magacooka makainũka kwao mũciĩ.
21 Olúwa si bojú wo Hana, ó sì lóyún, ó bí ọmọkùnrin mẹ́ta àti ọmọbìnrin méjì. Samuẹli ọmọ náà sì ń dàgbà níwájú Olúwa.
Nake Jehova akĩiguĩra Hana tha; akĩgĩa nda agĩciara aanake atatũ na airĩtu eerĩ. Nake mwana ũcio ti Samũeli agĩkũrĩra hau mbere ya Jehova.
22 Eli sì di arúgbó gidigidi, ó sì gbọ́ gbogbo èyí ti àwọn ọmọ rẹ̀ ṣe sí gbogbo Israẹli; àti bi wọ́n ti máa ń bá àwọn obìnrin sùn, tí wọ́n máa ń péjọ ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ.
Na rĩrĩ, Eli aarĩ mũkũrũ mũno, na nĩaiguaga maũndũ mothe marĩa ariũ ake meekaga Isiraeli guothe, na ũrĩa maakomaga na andũ-a-nja arĩa maatungataga itoonyero-inĩ rĩa Hema-ya-Gũtũnganwo.
23 Ó sì wí fún wọn pé, kí ni ó ti ri “Èétirí tí èmi fi ń gbọ́ irú nǹkan bẹ́ẹ̀ sí yín? Nítorí tí èmi ń gbọ́ iṣẹ́ búburú yín láti ọ̀dọ̀ gbogbo ènìyàn.
Nĩ ũndũ ũcio akĩmooria atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ gĩtũmaga mwĩke maũndũ ta maya? Nĩndĩraigua kuuma kũrĩ andũ othe ũhoro wa ciĩko ici cianyu cia waganu.
24 Bẹ́ẹ̀ kọ́ ẹ̀yin ọmọ mi, nítorí kì ṣe ìròyìn rere èmi gbọ́; ẹ̀yin mú ènìyàn Olúwa dẹ́ṣẹ̀.
Aca, ariũ akwa; ũhoro ũrĩa ndĩraigua ũkĩhunja gatagatĩ ka andũ a Jehova ti mwega.
25 Bí ẹnìkan bá ṣẹ̀ sí ẹnìkejì, onídàájọ́ yóò ṣe ìdájọ́ rẹ̀: ṣùgbọ́n bí ẹnìkan bá ṣẹ̀ sí Olúwa, ta ni yóò bẹ̀bẹ̀ fún un?” Wọn kò sì fi etí sí ohùn baba wọn, nítorí tí Olúwa ń fẹ́ pa wọ́n.
Mũndũ angĩhĩria mũndũ ũrĩa ũngĩ-rĩ, Ngai no amateithũrane; no mũndũ angĩhĩria Jehova-rĩ, nũũ ũngĩmũthaithanĩrĩra?” No rĩrĩ, aanake ake matiigana kũigua magĩkaanio nĩ ithe wao, nĩgũkorwo Jehova nĩatuĩte nĩekũmooraga.
26 Ọmọ náà Samuẹli ń dàgbà, ó sì rí ojúrere lọ́dọ̀ Olúwa, àti ènìyàn pẹ̀lú.
Nake mwana ũcio ti Samũeli agĩkũra, akĩnenehaga, akĩendagwo nĩ Jehova o na andũ.
27 Ènìyàn Ọlọ́run kan tọ Eli wá, ó sì wí fún un pé, “Báyìí ni Olúwa wí, ‘Èmi fi ara mi hàn ní gbangba fún ilé baba rẹ, nígbà tí wọ́n ń bẹ ní Ejibiti nínú ilé Farao.
Na rĩrĩ, mũndũ wa Ngai nĩokire kũrĩ Eli, akĩmwĩra atĩrĩ, “Jehova ekuuga ũũ: ‘Githĩ niĩ ndieguũrĩirie nyũmba ya thoguo rĩrĩa maarĩ Misiri watho-inĩ wa Firaũni?
28 Èmi sì yàn án kúrò láàrín gbogbo ẹ̀yà Israẹli láti jẹ́ àlùfáà mi, láti rú ẹbọ lórí pẹpẹ mi, láti fi tùràrí jóná, láti wọ efodu níwájú mi, èmi sì fi gbogbo ẹbọ tí ọmọ Israẹli máa ń fi iná sun fún ìdílé baba rẹ̀.
Ndathuurire thoguo kuuma mĩhĩrĩga-inĩ yothe ya Isiraeli atuĩke mũthĩnjĩri-Ngai wakwa, aambatage kĩgongona-inĩ gĩakwa, na acinage ũbumba, na ehumbage ebodi arĩ mbere yakwa. Ningĩ nĩndaheire nyũmba ya thoguo indo iria ciothe irutagwo nĩ andũ a Isiraeli cia maruta ma gũcinwo na mwaki.
29 Èéha ṣe tí ẹ̀yin fi tàpá sí ẹbọ àti ọrẹ mi, tí mo pàṣẹ ní ibùjókòó mi, ìwọ sì bu ọlá fún àwọn ọmọ rẹ jù mí lọ, tí ẹ sì fi gbogbo àṣàyàn ẹbọ Israẹli àwọn ènìyàn mi mú ara yín sanra.’
Nĩ kĩĩ gĩtũmĩte mũnyarare igongona rĩakwa na iruta, iria ndaathanire irutagwo irĩ cia gĩikaro gĩakwa? Nĩ kĩĩ gĩtũmĩte ũtĩĩe ariũ aku kũngĩra, mwĩnoragie na icunjĩ iria njega cia iruta o rĩothe rĩrĩa ndutagĩrwo nĩ andũ akwa a Isiraeli?’
30 “Nítorí náà Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí pé, ‘Èmi ti wí nítòótọ́ pé, ilé rẹ àti ilé baba rẹ, yóò máa rìn níwájú mi títí.’ Ṣùgbọ́n nísinsin yìí Olúwa wí pé, ‘Kí á má rí i! Àwọn tí ó bú ọlá fún mi ni èmi yóò bu ọlá fún, àti àwọn tí kò kà mí sí ni a ó sì ṣe aláìkàsí.
“Tondũ wa ũguo-rĩ, Jehova, Ngai wa Isiraeli, oigĩte atĩrĩ, ‘Nĩnderanĩire atĩ nyũmba yaku na nyũmba ya thoguo nĩigũtũũra indungatagĩra nginya tene.’ No rĩu Jehova oigĩte atĩrĩ, ‘Ũndũ ũcio ũrondaihĩrĩria! Arĩa mandĩĩte nĩndĩrĩmatĩĩaga, no arĩa maamenete nĩmarĩmenagwo.
31 Kíyèsi i, àwọn ọjọ́ ń bọ̀ tí èmi ó gé agbára rẹ kúrò, àti agbára baba rẹ, tí kì yóò sí arúgbó kan nínú ilé rẹ.
Hĩndĩ nĩĩroka rĩrĩa ngaaniina hinya waku na niine hinya wa andũ a nyũmba ya thoguo, nĩgeetha gũtikanakorwo na mũndũ mũkũrũ thĩinĩ wa nyũmba yaku,
32 Ìwọ yóò rí wàhálà ti Àgọ́, nínú gbogbo ọlá tí Ọlọ́run yóò fi fún Israẹli; kì yóò sí arúgbó kan nínú ilé rẹ láéláé.
nawe nĩũkona mĩnyamaro gĩikaro-inĩ gĩakwa. O na gũtuĩka ũndũ mwega nĩũgeekwo Isiraeli, thĩinĩ wa nyũmba yaku gũtirĩ hĩndĩ gũgaakorwo mũndũ mũkũrũ.
33 Ọkùnrin tí ó jẹ́ tìrẹ, tí èmi kì yóò gé kúrò ní ibi pẹpẹ mi ni a ó dá sí láti sọkún yọ lójú àti láti banújẹ́. Ṣùgbọ́n gbogbo irú-ọmọ ilé rẹ̀ ni a ó fi idà pa ní ààbọ̀ ọjọ́ wọn.
O mũndũ waku ũrĩa itakeheria kĩgongona-inĩ gĩakwa-rĩ, agaatigio no geetha agũtue mũtumumu na maithori, na aiguithagie ngoro yaku kĩeha, nacio njiaro ciaku ciothe irĩkuuaga o rĩrĩa ciatuĩka andũ agima.
34 “‘Kí ni ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí àwọn ọmọ ọkùnrin rẹ̀ méjèèjì, Hofini àti Finehasi, yóò jẹ́ àmì fún ọ—àwọn méjèèjì yóò kú ní ọjọ́ kan náà.
“‘Naguo ũndũ ũrĩa ũkũhaana kũrĩ ariũ aku eerĩ, Hofini na Finehasi, ũgaatuĩka kĩmenyithia kũrĩ wee na ariũ aku, o eerĩ magaakua mũthenya ũmwe.
35 Èmi yóò dìde fún ara mi láti gbé àlùfáà olódodo dìde fún ara mi, ẹni tí yóò ṣe gẹ́gẹ́ bí ohun tí ó wà ní ọkàn mi àti inú mi. Èmi yóò fi ẹsẹ̀ ilé rẹ̀ múlẹ̀ gbọningbọnin òun yóò sì ṣe òjíṣẹ́ níwájú ẹni òróró mi ní ọjọ́ gbogbo.
Na niĩ nĩngethuurĩra mũthĩnjĩri-Ngai mwĩhokeku, ũrĩa ũgeekaga kũringana na ũndũ ũrĩa ũrĩ ngoro-inĩ na meciiria-inĩ makwa. Nĩngahaanda nyũmba yake ĩtũũre ĩrũmĩte, nake nĩagatungataga mbere ya ũrĩa wakwa mũitĩrĩrie maguta hĩndĩ ciothe.
36 Nígbà náà olúkúlùkù ẹnikẹ́ni tí ó bá kù ní ìdílé yín, yóò jáde wá yóò sì foríbalẹ̀ níwájú rẹ̀ nítorí ẹyọ fàdákà àti nítorí èépá àkàrà àti ẹ̀bẹ̀ pé, “Jọ̀wọ́ yàn mí sí ọ̀kan nínú iṣẹ́ àwọn àlùfáà, kí èmi kí ó le máa rí oúnjẹ jẹ.”’”
Ningĩ mũndũ wothe ũrĩa ũgaatigara wa nyũmba yaku, nĩagooka amũinamĩrĩre nĩ ũndũ wa gĩcunjĩ kĩa betha na kenyũ komũ ka mũgate, amũthaithe amwĩre atĩrĩ, “Ta he wĩra ũmwe wa ũthĩnjĩri-Ngai nĩguo nyonage gĩa kũrĩa.”’”

< 1 Samuel 2 >