< 1 Kings 14 >
1 Ní àkókò náà Abijah ọmọ Jeroboamu sì ṣàìsàn,
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
2 Jeroboamu sì wí fún aya rẹ̀ pé, “Lọ, sì pa ara rẹ dà, kí wọn kí ó má ba à mọ̀ ọ́n ní aya Jeroboamu. Nígbà náà ni kí o lọ sí Ṣilo. Ahijah wòlíì wà níbẹ̀; ẹni tí ó sọ fún mi pé, èmi yóò jẹ ọba lórí àwọn ènìyàn yìí.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
3 Mú ìṣù àkàrà mẹ́wàá pẹ̀lú rẹ̀, àti àkàrà wẹ́wẹ́ àti ìgò oyin, kí o sì lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀. Òun yóò sì sọ fún ọ ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọmọkùnrin náà.”
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
4 Bẹ́ẹ̀ ni aya Jeroboamu sì ṣe bí ó ti wí, ó sì lọ sí ilé Ahijah ní Ṣilo. Ahijah kò sì ríran; ojú rẹ̀ ti fọ́ nítorí ogbó rẹ̀.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
5 Ṣùgbọ́n Olúwa ti sọ fún Ahijah pé, “Kíyèsi i, aya Jeroboamu ń bọ̀ wá béèrè nípa ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ, nítorí tí ó ṣàìsàn, báyìí báyìí ni kí ìwọ kí ó wí fún un. Nígbà tí ó bá dé, yóò ṣe ara rẹ̀ bí ẹlòmíràn.”
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
6 Bẹ́ẹ̀ ni ó sì rí, nígbà tí Ahijah sì gbọ́ ìró ẹsẹ̀ rẹ̀ ní ẹnu-ọ̀nà, ó sì wí pé, “Wọlé wá, aya Jeroboamu. Kí ló dé tí ìwọ fi ṣe ara rẹ bí ẹlòmíràn? A ti fi iṣẹ́ búburú rán mi sí ọ.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
7 Lọ, sọ fún Jeroboamu pé báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí, ‘Èmi sì gbé ọ ga láti inú àwọn ènìyàn, mo sì fi ọ́ jẹ olórí lórí Israẹli ènìyàn mi.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
8 Mo fa ìjọba náà ya kúrò ní ilé Dafidi, mo sì fi fún ọ ṣùgbọ́n, ìwọ kò dàbí Dafidi ìránṣẹ́ mi, tí ó pa àṣẹ mi mọ́, tí ó sì tọ̀ mí lẹ́yìn tọkàntọkàn rẹ̀, láti ṣe kìkì èyí tí ó tọ́ ní ojú mi.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
9 Ìwọ sì ti ṣe búburú ju gbogbo àwọn tí ó ti wà ṣáájú rẹ lọ. Ìwọ sì ti ṣe àwọn ọlọ́run mìíràn fún ara rẹ, àwọn òrìṣà tí a gbẹ́; o sì ti mú mi bínú, o sì ti gbé mi sọ sí ẹ̀yìn rẹ.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
10 “‘Nítorí èyí, Èmi yóò mú ibi wá sí ilé Jeroboamu. Èmi yóò ké gbogbo ọ̀dọ́mọkùnrin kúrò lọ́dọ̀ Jeroboamu, àti ọmọ ọ̀dọ̀ àti òmìnira ní Israẹli. Èmi yóò mú ilé Jeroboamu kúrò bí ènìyàn ti ń kó ìgbẹ́ kúrò, títí gbogbo rẹ̀ yóò fi tán.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
11 Ajá yóò jẹ ẹni Jeroboamu tí ó bá kú ní ìlú, àti ẹni tí ó bá kú ní igbó ni àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run yóò jẹ. Olúwa ti sọ ọ́!’
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
12 “Ní ti ìwọ, padà lọ ilé, nígbà tí o bá sì fi ẹsẹ̀ rẹ tẹ ìlú, ọmọ náà yóò kú.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
13 Gbogbo Israẹli yóò sì ṣọ̀fọ̀ fún un, wọn yóò sì sin ín. Òun nìkan ni a ó sì sin nínú ẹni tí ń ṣe ti Jeroboamu, nítorí lọ́dọ̀ rẹ̀ nìkan ni a ti rí ohun rere díẹ̀ sípa Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ní ilé Jeroboamu.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
14 “Olúwa yóò gbé ọba kan dìde fúnra rẹ̀ lórí Israẹli tí yóò ké ilé Jeroboamu kúrò. Ọjọ́ náà nìyìí! Kí ni? Àní nísinsin yìí.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
15 Olúwa yóò kọlu Israẹli, yóò sì dàbí koríko ti ń mì nínú omi. Yóò sì fa Israẹli tu kúrò ní ilẹ̀ rere yìí, tí ó ti fi fún àwọn baba wọn, yóò sì fọ́n wọn ká kọjá odò Eufurate, nítorí wọ́n ti rú ìbínú Olúwa nípa ṣíṣe ère Aṣerah.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
16 Yóò sì kọ Israẹli sílẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí Jeroboamu ti ṣẹ̀ àti tí ó mú Israẹli ṣẹ̀.”
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
17 Nígbà náà ni aya Jeroboamu sì dìde, ó sì lọ, ó sì lọ sí Tirsa. Bí ó sì ti fi ẹsẹ̀ tẹ ìloro ilé, ọmọdé náà sì kú.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
18 Wọ́n sì sin ín, gbogbo Israẹli sì ṣọ̀fọ̀ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti wí láti ẹnu ìránṣẹ́ rẹ̀, Ahijah wòlíì.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
19 Ìyókù ìṣe Jeroboamu, bí ó ti jagun, àti bí ó ti jẹ ọba, ni a kọ sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
20 Jeroboamu sì jẹ ọba fún ọdún méjìlélógún, ó sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀. Nadabu ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
21 Rehoboamu ọmọ Solomoni sì jẹ ọba ní Juda. Ó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógún nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ ọba, ó sì jẹ ọba ní ọdún mọ́kànlélógún ní Jerusalẹmu, ìlú tí Olúwa ti yàn nínú gbogbo ẹ̀yà Israẹli láti fi orúkọ rẹ̀ síbẹ̀. Orúkọ ìyá rẹ̀ sì ni Naama, ará Ammoni.
Cependant, Roboam, fils de Salomon, régnait sur Juda; il avait quarante et un ans quand il monta sur le trône, et il régna dix-sept ans à Jérusalem, dans la ville que, parmi toutes les tribus d'Israël, le Seigneur s'était choisie pour qu'y résidât son nom; sa mère, nommée Naama, était Ammonite.
22 Juda sì ṣe búburú níwájú Olúwa nípa ẹ̀ṣẹ̀ wọn tí wọ́n ti dá, wọ́n sì mú u jowú ju gbogbo èyí tí baba wọn ti ṣe lọ.
Roboam fit le mal devant le Seigneur, et il l'irrita, en faisant tout ce que faisaient ses pères quand ils tombaient dans le péché.
23 Wọ́n sì tún kọ́ ibi gíga fún ara wọn, àti ère òkúta àti òpó Aṣerah lórí gbogbo òkè gíga, àti lábẹ́ gbogbo igi tútù.
Le peuple se bâtit des hauts lieux et des colonnes; il eut des bois sacrés sur toutes les collines élevées; et il adora sous tous les arbres touffus.
24 Àwọn tí wọn jẹ́ ọkùnrin alágbèrè ojúbọ òrìṣà wà ní ilẹ̀ náà, àwọn ènìyàn náà sì ṣe gẹ́gẹ́ bí gbogbo ohun ìríra àwọn orílẹ̀-èdè tí Olúwa ti lé jáde kúrò níwájú àwọn ọmọ Israẹli.
Et il y eut une association dans la terre promise; il s'y commit toutes les abominations des peuples que le Seigneur avait exterminés devant la face des fils d'Israël.
25 Ó sì ṣe ní ọdún karùn-ún Rehoboamu, Ṣiṣaki ọba Ejibiti kọlu Jerusalẹmu.
Aussi, la cinquième année du règne de Roboam, Sésac, roi d'Égypte, marcha contre Jérusalem.
26 Ó sì kó ìṣúra ilé Olúwa lọ àti ìṣúra ilé ọba. Gbogbo rẹ̀ ni ó kó lọ, pẹ̀lú asà wúrà tí Solomoni ti ṣe.
Et il prit tous les trésors du temple du Seigneur, et tous les trésors du palais du roi, et les javelines d'or que David avait enlevées aux fils d'Adrazaar, roi de Suba, pour les placer à Jérusalem, et les armures d'or qu'avait fait fabriquer Salomon; Sésac emporta tout en Égypte.
27 Rehoboamu ọba sì ṣe asà idẹ ní ipò wọn, ó sì fi wọ́n sí ọwọ́ olórí àwọn olùṣọ́ tí ń ṣọ́ ìlẹ̀kùn ilé ọba.
Roboam remplaça les armures d'or par des armures d'airain, et il les mit sous la surveillance des chefs de ses coureurs, qui gardaient la porte de son palais.
28 Nígbàkígbà tí ọba bá sì lọ sí ilé Olúwa, wọ́n á rù wọ́n, wọ́n á sì mú wọn padà sínú yàrá olùṣọ́.
Et lorsque le roi entrait dans le temple du Seigneur, ses coureurs portaient les armures et les attachaient dans le dépôt des coureurs.
29 Ní ti ìyókù ìṣe Rehoboamu, àti gbogbo ohun tí ó ṣe, ǹjẹ́ a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda bí?
Quant au reste de l'histoire de Roboam, n'est-il pas écrit au livre des Faits et gestes des rois de Juda?
30 Ogun sì wà láàrín Rehoboamu àti Jeroboamu ní ọjọ́ wọn gbogbo.
Et il y eut une guerre continuelle entre Roboam et Jéroboam.
31 Rehoboamu sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín pẹ̀lú wọn ní ìlú Dafidi. Orúkọ ìyá rẹ̀ sì ni Naama; ará Ammoni. Abijah ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Et Roboam s'endormit avec ses pères; il fut enseveli auprès d'eux en la ville de David, et son fils Abiam le remplaça.