< 1 Chronicles 20 >

1 Ní àkókò àkọ́rọ̀ òjò, ni ìgbà tí àwọn ọba lọ sí ogun, Joabu ṣamọ̀nà àwọn ọ̀wọ́ ọmọ-ogun. Ó fi ilẹ̀ àwọn ará Ammoni ṣòfò. Ó lọ sí ọ̀dọ̀ Rabba. Ó sì fi ogun dúró tì í. Ṣùgbọ́n Dafidi dúró sí Jerusalẹmu Joabu kọlu Rabba, ó sì fi sílẹ̀ ní ìparun.
Na rĩrĩ, hĩndĩ ya kĩmera yakinya, ihinda rĩrĩa athamaki maathiiaga mbaara, Joabu agĩtongoria mbũtũ cia ita. Nake akĩananga bũrũri wa Aamoni, na agĩthiĩ Raba akĩrĩrigiicĩria, no Daudi agĩtigwo Jerusalemu. Joabu agĩtharĩkĩra Raba agĩtiga aarĩananga.
2 Dafidi mú adé kúrò lórí àwọn ọba wọn ìwọ̀n rẹ̀ dàbí i tálẹ́ǹtì wúrà, a sì tò ó jọ pẹ̀lú àwọn òkúta iyebíye. A sì gbé e ka orí Dafidi. Ó kó ọ̀pọ̀ ìkógun láti ìlú ńlá náà.
Daudi akĩruta mũthamaki wao thũmbĩ mũtwe, nayo yarĩ na ũritũ wa taranda ĩmwe ya thahabu, na nĩyagemetio na tũhiga twa goro, nayo ĩkĩigĩrĩrwo mũtwe wa Daudi. Nake agĩtaha indo nyingĩ mũno kuuma itũũra rĩu inene,
3 Ó sì kó gbogbo àwọn ènìyàn tí ó wà ní ibẹ̀ jáde, ó sì fi iṣẹ́ lé wọn lọ́wọ́ láti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ayùn àti ìtulẹ̀ onírin àti àáké. Dafidi ṣe eléyìí sí gbogbo àwọn ará ìlú Ammoni. Nígbà náà, Dafidi àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ padà sí Jerusalẹmu.
na akĩrutũrũra aikari akuo, akĩmahe wĩra wa gwatũra mbaũ na mĩthumeno, na kũruta wĩra na harũ cia igera na mathanwa. Ũguo nĩguo Daudi eekire matũũra mothe ma Amoni. Thuutha ũcio Daudi na mbũtũ ciake ciothe cia ita magĩcooka Jerusalemu.
4 Ní ẹ̀yìn èyí ni ogun bẹ́ sílẹ̀ ní Geseri pẹ̀lú àwọn ará Filistini, ní àkókò yìí ni Sibekai ará Huṣati pa Sipai, ọ̀kan lára àwọn ọmọ Refaimu, àti àwọn ará Filistini ni a ṣẹ́gun.
Mahinda macio-rĩ, gũkĩgĩa mbaara ya kũrũa na Afilisti kũu Gezeri. Hĩndĩ ĩyo Sibekai ũrĩa Mũhushathi akĩũraga Sipai, ũmwe wa njiaro cia Refai, nao Afilisti magĩtoorio biũ.
5 Nínú ogun mìíràn pẹ̀lú àwọn ará Filistini, Elhanani ọmọ Jairi pa Lahmi arákùnrin Goliati ará Gitti, ẹni ti ó ní ọ̀kọ̀ kan tí ó dàbí ọ̀pá ahunṣọ.
Mbaara-inĩ ĩngĩ makĩrũa na Afilisti, nake Elihanani mũrũ wa Jairu akĩũraga Lahami mũrũ wa nyina na Goliathũ, ũrĩa Mũgiiti, ũrĩa warĩ na itimũ rĩarĩ na mũtĩ waiganaga ta mũtĩ wa mũtumi ngoora.
6 Síbẹ̀síbẹ̀ nínú ogun mìíràn, tí ó wáyé ní Gati, ọkùnrin títóbi kan wà tí ó ní ìka mẹ́fà ní ọwọ́ rẹ̀ pẹ̀lú ìka mẹ́fà ní ẹsẹ̀ rẹ̀ mẹ́rìnlélógún lápapọ̀. Òun pẹ̀lú wá láti Rafa.
Ningĩ mbaara-inĩ ĩngĩ ĩrĩa yarũĩirwo Gathu, kwarĩ na mũndũ mũnene mũno, warĩ na ciara ithathatũ o guoko, na ciara ithathatũ o kũgũrũ, ciothe ciarĩ ciara mĩrongo ĩĩrĩ na inya. O nake aarĩ wa rũciaro rwa Rafa.
7 Nígbà tí ó fi Israẹli ṣẹ̀sín, Jonatani ọmọ Ṣimea, arákùnrin Dafidi sì pa á.
Rĩrĩa aanyũrũririe andũ a Isiraeli, Jonathani mũrũ wa Shimea, mũrũ wa nyina na Daudi, akĩmũũraga.
8 Wọ̀nyí ni ìran ọmọ Rafa ní Gati, wọ́n sì ṣubú sí ọwọ́ Dafidi àti àwọn ọkùnrin rẹ̀.
Acio nĩo maarĩ a rũciaro rwa Rafa wa kũu Gathu, nao makĩũragwo nĩ Daudi na andũ ake.

< 1 Chronicles 20 >