< 2 Chronicles 1 >

1 Solomoni ọmọ Dafidi fìdí ara rẹ̀ múlẹ̀ ṣinṣin lórí ìjọba rẹ̀. Nítorí tí Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ wà pẹ̀lú u rẹ̀, ó sì jẹ́ kí ó ga lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
Solomoni, mũrũ wa Daudi, nĩehaandire akĩrũma wega ũthamaki-inĩ wake, nĩgũkorwo Jehova Ngai wake aarĩ hamwe nake na akĩmũnenehia mũno makĩria.
2 Nígbà náà, Solomoni bá gbogbo Israẹli sọ̀rọ̀ sí àwọn alákòóso ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti àwọn alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún, sí àwọn adájọ́ àti sí gbogbo àwọn olórí Israẹli, àwọn olórí ìdílé
Nake Solomoni akĩarĩria andũ a Isiraeli othe: akĩarĩria anene a mbũtũ cia o ngiri ngiri, na anene a mbũtũ cia o igana igana, na aciiri, o na atongoria othe a kũu Isiraeli, na atongoria a nyũmba.
3 pẹ̀lú Solomoni, àti gbogbo àpéjọ lọ sí ibi gíga ní Gibeoni, nítorí àgọ́ Ọlọ́run fún pípàdé wà níbẹ̀, tí Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti pa ní aginjù.
Nake Solomoni na kĩũngano kĩu gĩothe makĩambata kũndũ kũrĩa gũtũũgĩru kũu Gibeoni, nĩgũkorwo Hema-ya-Gũtũnganwo ya Ngai nĩkuo yarĩ, ĩrĩa Musa ndungata ya Jehova aathondekeire kũu werũ-inĩ.
4 Nísinsin yìí, Dafidi ti gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run wá láti Kiriati-Jearimu sí ibi tí ó ti pèsè fún un, nítorí ó ti kọ́ àgọ́ fún un ni Jerusalẹmu.
Na rĩrĩ, Daudi nĩambatĩtie ithandũkũ rĩa Ngai kuuma Kiriathu-Jearimu akarĩiga harĩa aarĩthondekeire, tondũ nĩarĩambĩire hema kũu Jerusalemu.
5 Ṣùgbọ́n pẹpẹ idẹ tí Besaleli ọmọ Uri, ọmọ Huri, ti ṣe wà ní Gibeoni níwájú àgọ́ Olúwa, bẹ́ẹ̀ ni Solomoni àti gbogbo àpéjọ béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ níbẹ̀.
No kĩgongona gĩa gĩcango kĩrĩa gĩathondeketwo nĩ Bezaleli mũrũ wa Uri, mũrũ wa Huru, kĩarĩ Gibeoni mbere ya hema ĩrĩa nyamũre ya Jehova; nĩ ũndũ ũcio Solomoni na kĩũngano kĩu magĩthiĩ hau gũtuĩria ũhoro kuuma kũrĩ Jehova.
6 Solomoni gòkè lọ sí ibi pẹpẹ idẹ níwájú Olúwa ní ibi àgọ́ ìpàdé, ó sì rú ẹgbẹ̀rún ẹbọ sísun lórí rẹ̀.
Solomoni akĩambata kĩgongona-inĩ kĩu gĩa gĩcango o hau mbere ya Jehova thĩinĩ wa Hema-ya-Gũtũnganwo, na akĩrutĩra hau igũrũ wakĩo magongona ngiri ĩmwe ma njino.
7 Ní òru ọjọ́ náà, Ọlọ́run farahàn Solomoni, ó sì wí fún un pé, “Béèrè fún ohunkóhun tí ìwọ bá fẹ́ kí n fún ọ.”
Ũtukũ o ro ũcio-rĩ, Ngai akiumĩrĩra Solomoni, akĩmwĩra atĩrĩ, “Hooya kĩrĩa gĩothe ũkwenda ngũhe.”
8 Solomoni dá Ọlọ́run lóhùn pé, “Ìwọ ti fi àánú ńlá han Dafidi baba mi, ìwọ sì ti fi mí jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
Solomoni agĩcookeria Ngai atĩrĩ, “Nĩwekĩire baba Daudi maũndũ manene ma ũtugi na nĩũnduĩte mũthamaki ithenya rĩake.
9 Nísinsin yìí Olúwa Ọlọ́run, jẹ́ kí ìlérí rẹ sí baba à mi Dafidi wá sí ìmúṣẹ, nítorí ìwọ ti fi mí jẹ ọba lórí àwọn ènìyàn tí ó pọ̀ bí erùpẹ̀ ilẹ̀.
Na rĩrĩ, Wee Jehova Ngai, reke ũrĩa werĩire baba Daudi ũhinge, nĩgũkorwo nĩũnduĩte mũthamaki wa andũ aingĩ o ta rũkũngũ rwa thĩ.
10 Fún mi ní ọgbọ́n àti ìmọ̀, kí èmi kí ó lè máa wọ ilé kí ń sì máa jáde níwájú ènìyàn wọ̀nyí, nítorí ta ni ó le è ṣàkóso àwọn ènìyàn rẹ tí ó pọ̀ yanturu wọ̀nyí?”
He ũũgĩ na ũmenyo, nĩguo ndongoragie andũ aya, nĩ ũndũ-rĩ, nũũ ũngĩhota gwatha andũ aya aku aingĩ ũũ?”
11 Ọlọ́run wí fún Solomoni pé, “Níwọ́n ìgbà tí ó jẹ́ pé ìfẹ́ ọkàn rẹ nìyí, tí ìwọ kò sì béèrè, fún ọrọ̀, ọlá tàbí ọ̀wọ̀, tàbí fún ikú àwọn ọ̀tá rẹ, àti nígbà tí ìwọ kò ti béèrè fún ẹ̀mí gígùn, ṣùgbọ́n tí ìwọ béèrè fún ọgbọ́n àti ìmọ̀ láti ṣàkóso àwọn ènìyàn mi tí èmi fi ọ́ jẹ ọba lé lórí.
Ngai akĩĩra Solomoni atĩrĩ, “Kuona atĩ ũndũ ũyũ nĩguo wendi wa ngoro yaku na ndũnahooya ũtonga, kana kũgĩa indo nyingĩ o na kana gĩtĩĩo, kana gĩkuũ gĩa thũ ciaku, na kuona atĩ ndũnahooya ũtũũre muoyo matukũ maingĩ, no wahooya ũũgĩ na ũmenyo wa gwathaga andũ akwa arĩa ngũtuĩte mũthamaki wao-rĩ,
12 Nítorí náà, ọgbọ́n àti ìmọ̀ ni a ó fi fún ọ, Èmi yóò sì fún ọ ní ọrọ̀, ọlá àti ọ̀wọ̀, irú èyí tí ọba ti ó wà ṣáájú rẹ kò ní, tí àwọn tí ń bọ̀ lẹ́yìn rẹ kò sì ní ní irú rẹ̀.”
nĩ ũndũ ũcio nĩũkũheo ũũgĩ na ũmenyo. O na ningĩ nĩngũkũhe ũtonga, na indo nyingĩ o na gĩtĩĩo, iria itarĩ mũthamaki ũrĩ wakorwo nacio mbere ĩyo, na gũtarĩ mũthamaki ũkaagĩa nacio thuutha waku.”
13 Nígbà náà ni Solomoni sì ti ibi gíga Gibeoni lọ sí Jerusalẹmu láti iwájú àgọ́ ìpàdé. Ó sì jẹ ọba lórí Israẹli.
Ningĩ Solomoni agĩthiĩ Jerusalemu oimĩte handũ harĩa hatũũgĩru kũu Gibeoni hau mbere ya Hema-ya-Gũtũnganwo. Nake agĩthamakĩra Isiraeli.
14 Solomoni kó kẹ̀kẹ́ àti ẹṣin jọ, ó sì ní ẹgbàáje kẹ̀kẹ́ àti ẹgbàá mẹ́fà ẹlẹ́ṣin, tí ó kó pamọ́ sí ìlú kẹ̀kẹ́ ogun àti pẹ̀lú rẹ̀ ni Jerusalẹmu.
Solomoni nĩacookanĩrĩirie ngaari cia ita na mbarathi; aarĩ na ngaari cia ita 1,400 na mbarathi 12,000 iria aigĩte matũũra-inĩ manene ma ngaari cia ita, na akaiga iria ingĩ hakuhĩ nake kũu Jerusalemu.
15 Ọba náà ṣe fàdákà àti wúrà gẹ́gẹ́ bí ó ti wọ́pọ̀ ní Jerusalẹmu bí òkúta, àti kedari ó pọ̀ bí igi sikamore ní àwọn ẹsẹ̀ òkè.
Mũthamaki nĩatũmire betha na thahabu cingĩhe Jerusalemu o ta mahiga, mĩtarakwa nayo yarĩ mĩingĩ o ta mĩkũyũ ĩrĩa ĩrĩ magũrũ-inĩ ma irĩma.
16 Àwọn ẹṣin Solomoni ní a gbà láti ìlú òkèrè Ejibiti àti láti kún ọ̀gbọ̀ oníṣòwò ti ọba ni gba okun náà ní iye kan.
Mbarathi cia Solomoni cioimaga Misiri na kuuma Kilikia, nao onjorithia a mũthamaki maacigũraga kuuma Kilikia.
17 Wọ́n ra kẹ̀kẹ́ kan láti Ejibiti. Fún ẹgbẹ̀ta ṣékélì fàdákà àti ẹṣin kan fún ọgọ́rin méjìdínláàádọ́ta. Wọ́n ko wọn lọ sọ́dọ̀ àwọn ọba mìíràn ti Hiti àti ti àwọn ará Aramu.
Maagũraga ngaari ĩmwe ya ita kuuma Misiri cekeri 600 cia betha, nayo mbarathi ĩmwe ĩkoima cekeri 150. Ningĩ nĩmacookaga magacitwara ikenderio athamaki othe a Ahiti na a Suriata.

< 2 Chronicles 1 >