< Jeremija 45 >

1 Beseda, ki jo je prerok Jeremija spregovoril Nerijájevemu sinu Baruhu, ko je zapisal te besede v knjigo pri Jeremijevih ustih, v četrtem letu Jojakíma, Jošíjevega sina, Judovega kralja, rekoč:
Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Jeremiah wòlíì sọ fún Baruku ọmọ Neriah ní ọdún kẹrin ti Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda. Lẹ́yìn tí Baruku ti kọ sínú ìwé kíká àwọn ọ̀rọ̀ tí Jeremiah ti ń sọ:
2 »Tako govori Gospod, Izraelov Bog, tebi, oh Baruh.
“Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ fún ọ, Baruku.
3 Rekel si: ›Gorje mi sedaj! Kajti Gospod je dodal žalost k moji bridkosti; oslabel sem v svojem vzdihovanju in ne najdem počitka.‹
Ìwọ wí pé, ‘Ègbé ni fún mi! Olúwa ti fi ìbànújẹ́ kún ìrora mi, àárẹ̀ mú mi nínú ẹ̀dùn mi, èmi kò sì rí ìsinmi.’”
4 Tako mu boš rekel: › Gospod tako govori: ›Glej, to, kar sem zgradil, bom porušil in to, kar sem zasadil, bom izruval, celo to celotno deželo.
Olúwa wí pé sọ èyí fún un, “Èyí ni Ọlọ́run sọ: ‘Èyí tí èmi ti kọ́ ni èmi yóò wò lulẹ̀, àti èyí tí èmi ti gbìn ni èmi yóò fàtu, àní ní orí gbogbo ilẹ̀.
5 In ti zase iščeš velike stvari? Ne išči jih, kajti glej, privedel bom zlo nad vse meso, ‹ govori Gospod, ›toda tvoje življenje ti bom dal za plen v vseh krajih, kamor greš.«
Ṣé ìwọ sì ń wá ohun títóbi fún ara rẹ? Nítorí náà, má ṣe wá wọn. Èmi yóò mú ibi wá sí orí àwọn ènìyàn gbogbo ni Olúwa wí, ṣùgbọ́n níbikíbi tí ìwọ bá lọ ni èmi yóò jẹ́ kí o sá àsálà pẹ̀lú ẹ̀mí rẹ.’”

< Jeremija 45 >