< Psalmii 87 >

1 Un psalm sau o cântare pentru fiii lui Core. Temelia lui este în munții sfinți.
Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin. Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
2 DOMNUL iubește porțile Sionului mai mult decât toate locuințele lui Iacob.
Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.
3 Lucruri glorioase sunt vorbite despre tine, cetatea lui Dumnezeu. (Selah)
Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀, ìlú Ọlọ́run,
4 Voi aminti despre Rahab și Babilon celor ce mă cunosc, iată, Filistia și Tirul, cu Etiopia; acesta s-a născut acolo.
“Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi: Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi, yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’”
5 Și despre Sion se va spune: Acesta și acela s-a născut în ea, și însuși cel preaînalt o va întemeia.
Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ, “Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀, àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”
6 DOMNUL va număra, când va înscrie poporul, că acesta s-a născut acolo. (Selah)
Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀: “Eléyìí ni a bí ní Sioni.”
7 Tot așa cântăreții și instrumentiștii vor fi acolo, toate izvoarele mele sunt în tine.
Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu ohun èlò orin yóò wí pé, “Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”

< Psalmii 87 >