< Thaburi 60 >
1 Thaburi ya Daudi Wee Ngai nĩũtũtiganĩirie na ũgatũharagania; ũkoretwo ũtũrakarĩire, no rĩu tũcookerere!
Fún adarí orin. Tí ohùn “Lílì ti Májẹ̀mú.” Miktamu ti Dafidi. Fún ìkọ́ni. Nígbà tí ó bá Aramu-Naharaimu àti Siria-Soba jà, àti nígbà tí Joabu yípadà tí ó sì pa ẹgbẹ̀rún méjìlá àwọn ará Edomu ní àfonífojì Iyọ̀. Ìwọ ti kọ̀ wá sílẹ̀, Ọlọ́run, ìwọ ti tú wa ká, ìwọ ti bínú nísinsin yìí, tún ara rẹ yípadà sí wa.
2 Nĩũthingithĩtie bũrũri na ũkawatũra; thinga mĩatũka yaguo, nĩgũkorwo nĩũrenyenya.
Ìwọ ti mú ilẹ̀ wárìrì, ìwọ ti fọ́ ọ; mú fífọ́ rẹ̀ bọ̀ sípò, nítorí tí ó mì.
3 Nĩũtũmĩte andũ aku makorwo na mahinda maritũ; ũmanyuithĩtie ndibei magathiĩ magĩtũgũũgaga.
Ìwọ ti fi ìgbà ewu han àwọn ènìyàn rẹ; ìwọ fún wa ní wáìnì tí ó máa ń ta wá gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n.
4 No rĩrĩ, andũ arĩa magwĩtigĩrĩte-rĩ, nĩũmahaicĩirie bendera, nĩguo metharagĩre harĩ yo mona arĩa mamarathaga na ũta.
Àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀, ní ìwọ fi ọ̀págun fún kí a lè fihàn nítorí òtítọ́. (Sela)
5 Tũhonokie na ũtũteithie na guoko gwaku kwa ũrĩo, nĩguo arĩa wendete mahonoke.
Fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ gbà wá, kí o sì ràn wá lọ́wọ́, kí a lè gba àwọn tí o fẹ́ là.
6 Ngai nĩarĩtie arĩ handũ hake harĩa haamũre, akoiga atĩrĩ: “Nĩngatũranga Shekemu ndĩ na gĩkeno kĩingĩ, na thimĩre andũ akwa Gĩtuamba gĩa Sukothu.
Ọlọ́run ti sọ̀rọ̀ láti ibi mímọ́ rẹ̀: “Ní ayọ̀, èmi ó pọ Ṣekemu jáde èmi ó sì wọ́n àfonífojì Sukkoti.
7 Gileadi nĩ gwakwa, o na Manase no gwakwa; Efiraimu nĩ ngũbia yakwa ya kĩgera, na Juda nĩ rũthanju rwakwa rwa ũthamaki.
Tèmi ni Gileadi, tèmi sì ni Manase; Efraimu ni àṣíborí mi, Juda sì ni ọ̀pá àṣẹ mi.
8 Moabi nĩ kĩraĩ gĩakwa gĩa gwĩthambĩra, na Edomu nĩho njikagia kĩraatũ gĩakwa; nyanagĩrĩra nĩ ũrĩa ndooretie bũrũri wa Filistia.”
Moabu ní ìkòkò ìwẹsẹ̀ mi, lórí Edomu ní mo bọ́ bàtà mi sí; lórí Filistia ni mo kígbe ayọ̀.”
9 Nũũ ũkũnginyia itũũra rĩrĩa inene rĩirigĩre? Nũũ ũkũndongoria andware Edomu?
Ta ni yóò mú mi wá sí ìlú olódi nì? Ta ni yóò tọ́ mí lọ sí Edomu?
10 Githĩ tiwe, Wee Ngai, o Wee ũtũregete, na ũgatiga gũtwarana na mbũtũ ciitũ cia ita?
Kì í ha ń ṣe ìwọ, Ọlọ́run, tí ó ti kọ̀ wá sílẹ̀ tí o kò sì bá ogun wa jáde mọ́?
11 Tũteithie, ũtũhootanĩre harĩ thũ ciitũ, nĩgũkorwo ũteithio wa mũndũ nĩ wa tũhũ.
Fún wa ní ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn ọ̀tá, nítorí asán ni ìrànlọ́wọ́ ènìyàn.
12 Ngai arĩ hamwe na ithuĩ nĩtũkũhootana, na nĩakarangĩrĩria thũ ciitũ thĩ.
Nípa Ọlọ́run ni a óò ní ìṣẹ́gun, yóò sì tẹ àwọn ọ̀tá wa mọ́lẹ̀.