< Luka 4 >

1 Nake Jesũ akiuma kũu Jorodani aiyũrĩtwo nĩ Roho Mũtheru, agĩtwarwo nĩ Roho werũ-inĩ,
Jesu sì kún fún Ẹ̀mí Mímọ́, ó padà ti Jordani wá, a sì ti ọwọ́ Ẹ̀mí darí rẹ̀ sí ijù,
2 kũrĩa aagereirio nĩ mũcukani matukũ mĩrongo ĩna. Ndaarĩĩaga kĩndũ matukũ-inĩ macio, namo maathira agĩkorwo arĩ mũhũũtu.
Ogójì ọjọ́ ni a fi dán an wò lọ́wọ́ èṣù. Kò sì jẹ ohunkóhun ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì: nígbà tí wọ́n sì parí, lẹ́yìn náà ni ebi wá ń pa á.
3 Nake mũcukani akĩmwĩra atĩrĩ, “Angĩkorwo wee nĩwe Mũrũ wa Ngai, ĩra ihiga rĩrĩ rĩtuĩke mũgate.”
Èṣù sì wí fún un pé, “Bí ìwọ bá ṣe Ọmọ Ọlọ́run, pàṣẹ fún òkúta yìí kí ó di àkàrà.”
4 Nake Jesũ akĩmĩcookeria atĩrĩ, “Nĩ kwandĩkĩtwo atĩrĩ: ‘To mũgate wiki ũngĩtũũria mũndũ muoyo.’”
Jesu sì dáhùn, ó wí fún un pé, “A ti kọ̀wé rẹ̀ pé, ‘Ènìyàn kì yóò wà láààyè nípa àkàrà nìkan.’”
5 Ningĩ mũcukani akĩmũtwara handũ hatũũgĩru mũno, na gwa kahinda kanini mũno akĩmuonia mothamaki mothe ma gũkũ thĩ.
Lójúkan náà, èṣù sì mú un lọ sí orí òkè gíga, ó sì fi gbogbo ilẹ̀ ọba ayé hàn án.
6 Agĩcooka akĩmwĩra atĩrĩ, “Nĩngũkũhe wathani wa kũu guothe na riiri wakuo wothe, nĩgũkorwo nĩiheanĩtwo kũrĩ niĩ, na no ndĩciheane kũrĩ mũndũ o wothe ũrĩa ingĩenda kũhe.
Èṣù sì wí fún un pé, “Ìwọ ni èmi ó fi gbogbo agbára yìí àti ògo wọn fún: nítorí á sá ti fi fún mi. Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì wù mí, èmi a fi í fún.
7 Nĩ ũndũ ũcio ũngĩnyinamĩrĩra ũhooe, mothe megũtuĩka maku.”
Ǹjẹ́ bí ìwọ bá foríbalẹ̀ fún mi, gbogbo rẹ̀ ni yóò jẹ́ tìrẹ.”
8 Jesũ akĩmũcookeria, akĩmwĩra atĩrĩ, “Nĩ kwandĩkĩtwo atĩrĩ: ‘Hooyaga Mwathani Ngai waku na ũmũtungatagĩre o we wiki.’”
Jesu sì dáhùn ó sì wí fún un pé, “Kúrò lẹ́yìn mi, Satani, nítorí tí a kọ̀wé rẹ̀ pé, ‘Ìwọ foríbalẹ̀ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ, òun nìkan ṣoṣo ni kí ìwọ kí ó sì máa sìn.’”
9 Nake mũcukani akĩmũtwara Jerusalemu, na akĩmũrũgamia gathũrũmũndũ-inĩ ka hekarũ, akĩmwĩra atĩrĩ, “Angĩkorwo wee nĩwe Mũrũ wa Ngai, wĩgũithie thĩ kuuma haha.
Èṣù sì mú un lọ sí Jerusalẹmu, ó sì gbé e lé ibi ṣóńṣó tẹmpili, ó sì wí fún un pé, “Bí ìwọ bá ṣe Ọmọ Ọlọ́run, bẹ́ sílẹ̀ fún ara rẹ láti ibí yìí.
10 Nĩgũkorwo nĩ kwandĩkĩtwo atĩrĩ: “‘Nĩagaatha araika ake nĩ ũndũ waku makũmenyerere wega;
A sá ti kọ̀wé rẹ̀ pé, “‘Yóò pàṣẹ fún àwọn angẹli rẹ̀ nítorí rẹ, láti máa ṣe ìtọ́jú rẹ;
11 ningĩ nĩmagakwanĩrĩria na moko mao, nĩgeetha ndũkaringwo kũgũrũ nĩ ihiga.’”
àti pé ní ọwọ́ wọn ni wọn ó gbé ọ sókè, kí ìwọ kí ó má ba à fi ẹsẹ̀ rẹ gbún òkúta.’”
12 Nake Jesũ akĩmũcookeria atĩrĩ, “Maandĩko moigĩte atĩrĩ: ‘Ndũkanagerie Mwathani Ngai waku.’”
Jesu sì dáhùn ó wí fún un pé, “A ti kọ́ pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ dán Olúwa Ọlọ́run rẹ wò.’”
13 Rĩrĩa mũcukani aarĩkirie kũmũgeria na njĩra ciothe-rĩ, akĩmũtiga nginya ihinda rĩrĩa rĩagĩrĩire rĩkoneka.
Nígbà tí èṣù sì parí ìdánwò náà gbogbo, ó fi í sílẹ̀ lọ fun sá à kan.
14 Nake Jesũ agĩcooka Galili arĩ na hinya wa Roho, nayo ngumo yake ĩkĩhunja kũu bũrũri ũcio wothe.
Jesu sì fi agbára Ẹ̀mí padà wá sí Galili, òkìkí rẹ̀ sì kàn kálẹ̀ ní gbogbo agbègbè tí ó yí i ká.
15 Nake nĩarutanaga thunagogi-inĩ ciao, nao andũ othe makĩmũkumia.
Ó sì ń kọ́ni nínú Sinagọgu wọn; a ń yìn ín lógo láti ọ̀dọ̀ gbogbo àwọn ènìyàn wá.
16 Na rĩrĩ, nĩathiire Nazarethi, kũrĩa aarereirwo, na agĩtoonya thunagogi mũthenya wa Thabatũ, o ta ũrĩa aamenyerete gwĩka. Nake akĩrũgama na igũrũ athome Maandĩko.
Ó sì wá sí Nasareti, níbi tí a gbé ti tọ́ ọ dàgbà: bí ìṣe rẹ̀ ti rí, ó sì wọ inú Sinagọgu lọ ní ọjọ́ ìsinmi, ó sì dìde láti kàwé.
17 Akĩnengerwo ibuku rĩa gĩkũnjo rĩa mũnabii Isaia. Akĩrĩkũnjũra, akĩona harĩa handĩkĩtwo atĩrĩ:
A sì fi ìwé wòlíì Isaiah fún un. Nígbà tí ó sì ṣí ìwé náà, ó rí ibi tí a gbé kọ ọ́ pé:
18 “Roho wa Mwathani arĩ igũrũ rĩakwa, nĩ ũndũ nĩanjitĩrĩirie maguta nĩguo hunjagĩrie arĩa athĩĩni Ũhoro-ũrĩa-Mwega. Nĩandũmĩte thiĩ nyanĩrĩre kuohorwo kwa arĩa moheetwo, na atĩ arĩa atumumu nĩmegũcooka kuona, na njohorithie arĩa mahinyĩrĩirio,
“Ẹ̀mí Olúwa ń bẹ lára mi, nítorí tí ó fi àmì òróró yàn mí láti wàásù ìyìnrere fún àwọn òtòṣì. Ó ti rán mi wá láti wàásù ìdásílẹ̀ fún àwọn ìgbèkùn, àti ìmúnríran fún àwọn afọ́jú, àti láti jọ̀wọ́ àwọn tí a pa lára lọ́wọ́,
19 ningĩ nyanĩrĩre mwaka wa gwĩtĩkĩrĩka wa Mwathani.”
láti kéde ọdún ojúrere Olúwa.”
20 Agĩcooka agĩkũnja ibuku rĩu rĩa gĩkũnjo, agĩcookeria mũmenyereri wa thunagogi, agĩikara thĩ. Nao andũ arĩa othe maarĩ thunagogi makĩmũrora.
Ó sì pa ìwé náà dé, ó fi í fún ìránṣẹ́, ó sì jókòó. Gbogbo àwọn tí ó ń bẹ nínú Sinagọgu sì tẹjúmọ́ ọn.
21 Nake akĩambĩrĩria kwaria, akĩmeera atĩrĩ, “Ũmũthĩ maandĩko maya nĩ mahingio mũkĩĩiguagĩra.”
Ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í wí fún wọn pé, “Lónìí ìwé mímọ́ yìí ṣẹ ní etí yín.”
22 Nao andũ othe makĩmũgaatha na makĩgegio mũno nĩ ciugo njega iria cioimaga kanua gake. Makĩũrania atĩrĩ, “Githĩ ũyũ ti mũrũ wa Jusufu?”
Gbogbo wọn sì jẹ́rìí rẹ̀, háà sì ṣe wọ́n sí ọ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ tí ń jáde ní ẹnu rẹ̀, wọ́n sì wí pé, “Ọmọ Josẹfu kọ́ yìí?”
23 Nake Jesũ akĩmeera atĩrĩ, “Ti-itherũ nĩ mũkũnjĩĩra thimo ĩrĩa yugaga atĩrĩ, ‘Ndagĩtarĩ, wĩĩhonie wee mwene! Maũndũ marĩa tũiguĩte atĩ nĩ wekire kũu Kaperinaumu meeke gũkũ itũũra-inĩ rĩaku.’”
Jesu sì wí fún wọn pé, “Lóòótọ́ ni ẹ̀yin ó pa òwe yìí sí mi pé, ‘Oníṣègùn, wo ara rẹ̀ sàn! Àwọn ohun tí àwa gbọ́ pé o ti ọwọ́ rẹ ṣe ní Kapernaumu, ṣe é níhìn-ín yìí pẹ̀lú ní ilẹ̀ ara rẹ.’”
24 Agĩthiĩ na mbere kuuga atĩrĩ, “Ngũmwĩra na ma, gũtirĩ mũnabii wĩtĩkagĩrwo itũũra-inĩ rĩake.
Ó sì wí pé, “Lóòótọ́ ni mo wí fún un yín, kò sí wòlíì tí a tẹ́wọ́gbà ní ilẹ̀ baba rẹ̀.
25 Ngũmwĩra atĩrĩ na ma, nĩ kwarĩ atumia aingĩ a ndigwa Isiraeli matukũ-inĩ ma Elija, rĩrĩa igũrũ rĩarĩ ihinge mĩaka ĩtatũ na nuthu, na ngʼaragu nene ĩkĩiyũra bũrũri wothe.
Ṣùgbọ́n mo wí fún un yín nítòótọ́, opó púpọ̀ ni ó wà ní Israẹli nígbà ọjọ́ wòlíì Elijah, nígbà tí ọ̀run fi sé ní ọdún mẹ́ta òun oṣù mẹ́fà, nígbà tí ìyàn ńlá fi mú ká ilẹ̀ gbogbo.
26 No Elija ndaigana gũtũmwo kũrĩ o na ũmwe wao, tiga kũrĩ mũtumia wa ndigwa ũrĩa watũire itũũra rĩa Zarefathu kũu bũrũri wa Sidoni.
Kò sì sí ẹnìkan nínú wọn tí a rán Elijah sí, bí kò ṣe sí obìnrin opó kan ní Sarefati, ìlú kan ní Sidoni.
27 Ningĩ nĩ kwarĩ andũ aingĩ maarĩ na mangũ thĩinĩ wa Isiraeli ihinda rĩa Elisha ũrĩa mũnabii, no gũtirĩ mũndũ o na ũmwe wao wahonirio tiga Naamani ũrĩa Mũsuriata.”
Adẹ́tẹ̀ púpọ̀ ní sì ń bẹ ní Israẹli nígbà wòlíì Eliṣa; kò sì ṣí ọ̀kan nínú wọn tí a wẹ̀nùmọ́, bí kò ṣe Naamani ará Siria.”
28 Andũ othe arĩa maarĩ thĩinĩ wa thunagogi nĩmarakarire mũno rĩrĩa maiguire ũguo.
Nígbà tí gbogbo àwọn tí ó wà nínú Sinagọgu gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, inú bi wọ́n gidigidi,
29 Magĩũkĩra makĩmũrutũrũra kuuma itũũra-inĩ rĩu, makĩmũtwara rwere-inĩ rwa karĩma harĩa itũũra rĩu rĩakĩtwo, nĩguo mamũikie na kũu kĩharũrũka-inĩ.
wọ́n sì dìde, wọ́n tì í sóde sí ẹ̀yìn ìlú, wọ́n sì fà á lọ sí bèbè òkè níbi tí wọ́n gbé tẹ ìlú wọn dó, kí wọn bá à lè sọ sílẹ̀ ní ògèdèǹgbé.
30 Nowe Jesũ akĩgerera gatagatĩ-inĩ ka andũ, agĩĩthiĩra.
Ṣùgbọ́n ó kọjá láàrín wọn, ó bá tirẹ̀ lọ.
31 Agĩcooka agĩikũrũka, agĩthiĩ Kaperinaumu, itũũra rĩarĩ Galili, na mũthenya wa Thabatũ akĩambĩrĩria kũruta andũ.
Ó sì sọ̀kalẹ̀ wá sí Kapernaumu, ìlú kan ní Galili, ó sì ń kọ́ wọn ní ọjọ́ ìsinmi.
32 Nao andũ makĩgega nĩ ũndũ wa ũrutani wake, tondũ ndũmĩrĩri yake yarĩ ya wathani.
Ẹnu sì yà wọ́n sí ẹ̀kọ́ rẹ̀: nítorí tàṣẹtàṣẹ ni ọ̀rọ̀ rẹ̀.
33 Na rĩrĩ, kũu thĩinĩ wa thunagogi nĩ kwarĩ na mũndũ warĩ na ndaimono, nĩyo ngoma thũku. Nake akĩanĩrĩra na mũgambo mũnene, akiuga atĩrĩ,
Ọkùnrin kan sì wà nínú Sinagọgu, ẹni tí ó ní ẹ̀mí àìmọ́, ó kígbe ní ohùn rara,
34 “Hĩ! Ũrenda atĩa na ithuĩ, wee Jesũ wa Nazarethi? Ũũkĩte gũtũniina? Nĩngũũĩ, we nĩwe ũrĩa Mũtheru wa Ngai!”
“Ó wí pé, kín ni ṣe tàwa tìrẹ, Jesu ará Nasareti? Ìwọ́ wá láti pa wá run bí? Èmí mọ ẹni tí ìwọ í ṣe, Ẹni Mímọ́ Ọlọ́run.”
35 Nake Jesũ akĩmĩkũma, akĩmĩĩra atĩrĩ, “Kira, na uume thĩinĩ wake!” Nayo ndaimono ĩyo ĩkĩgũithia mũndũ ũcio thĩ hau mbere yao othe, ĩkiuma na ndĩamũtihirie.
Jesu sì bá a wí gidigidi, ó wí fun pe, “Pa ẹnu rẹ mọ́, kí o sì jáde lára rẹ̀.” Nígbà tí ẹ̀mí èṣù náà sì gbé e ṣánlẹ̀ ní àwùjọ, ó jáde kúrò lára rẹ̀, kò sì pa á lára.
36 Nao andũ othe makĩgega makĩũrania atĩrĩ, “Kaĩ ũrutani ũyũ ũhaana atĩa? Araatha ngoma thũku arĩ na wathani na hinya, nacio ikoima!”
Ẹnu sì ya gbogbo wọn, wọ́n sì ń bá ara wọn sọ wí pé, “Irú ẹ̀kọ́ kín ni èyí? Nítorí pẹ̀lú àṣẹ àti agbára ni ó fi bá àwọn ẹ̀mí àìmọ́ wí, wọ́n sì jáde kúrò.”
37 Nayo ngumo yake ĩkĩhunja kũrĩa guothe kwariganĩtie na kũu.
Òkìkí rẹ̀ sì kàn níbi gbogbo ní agbègbè ilẹ̀ náà yíká.
38 Nake Jesũ akiuma thunagogi, agĩthiĩ mũciĩ gwa Simoni. Na rĩrĩ, nyina wa mũtumia wa Simoni aarĩ mũrũaru mũrimũ wa kũhiũha mwĩrĩ mũno, nao magĩthaitha Jesũ nĩ ũndũ wake.
Nígbà tí ó sì dìde kúrò nínú Sinagọgu, ó sì wọ̀ ilé Simoni lọ; ibà sì ti dá ìyá ìyàwó Simoni dùbúlẹ̀, wọ́n sì bẹ̀ ẹ́ nítorí rẹ̀.
39 Nĩ ũndũ ũcio, akĩinamĩrĩra harĩ we, na agĩatha mũrimũ ũcio uume mwĩrĩ wake, naguo ũkiuma. Nake mũtumia ũcio agĩũkĩra o rĩmwe na akĩambĩrĩria kũmatungatĩra.
Ó sì súnmọ́ ọ, ó bá ibà náà wí; ibà sì náà sì fi sílẹ̀. O sì dìde lọ́gán, ó ń ṣe ìránṣẹ́ fún wọn.
40 Na rĩrĩa riũa rĩathũaga, andũ makĩrehera Jesũ andũ arĩa othe maarĩ na mĩrimũ ngũrani, nake akĩmaigĩrĩra moko o mũndũ o mũndũ, akĩmahonia.
Nígbà tí oòrùn sì ń wọ̀, àwọn ènìyàn gbe àwọn aláìsàn, tó ní onírúurú àìsàn wá sọ́dọ̀ Jesu; ó sì fi ọwọ́ lé olúkúlùkù wọn, ó sì mú wọn láradá.
41 O na ningĩ ndaimono ikiuma andũ aingĩ, ikĩanagĩrĩra atĩrĩ, “Wee nĩwe Mũrũ wa Ngai!” Nowe agĩcikaania na agĩcigiria ciarie, tondũ nĩcioĩ atĩ nĩwe Kristũ.
Àwọn ẹ̀mí èṣù sì jáde lára ẹni púpọ̀ pẹ̀lú, wọ́n ń kígbe, wí pé, “Ìwọ ni Ọmọ Ọlọ́run!” Ó sì ń bá wọn wí kò sì jẹ́ kí wọn kí ó fọhùn, nítorí tí wọ́n mọ̀ pé Òun ni Kristi náà.
42 Na gwakĩa-rĩ, Jesũ akiumagara agĩthiĩ kũndũ gũtaarĩ andũ. Nao andũ makĩmũcaria, na rĩrĩa maakinyire harĩa aarĩ, makĩgeria kũmũgirĩrĩria ndakoime kũu amatige.
Nígbà tí ilẹ̀ sì mọ́, Jesu sì jáde lọ, ó sì ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀. Ìjọ ènìyàn sì ń wá a kiri, wọ́n sì tọ̀ ọ́ wá, wọ́n sì dá a dúró, nítorí kí ó má ba à lọ kúrò lọ́dọ̀ wọn.
43 Nowe akĩmeera atĩrĩ, “No nginya hunjie Ũhoro-ũrĩa-Mwega wa ũthamaki wa Ngai matũũra-inĩ marĩa mangĩ o namo, nĩ ũndũ nĩkĩo ndaatũmirwo.”
Ṣùgbọ́n ó sì wí fún wọn pé, “Èmi kò lè ṣàìmá wàásù ìyìnrere ti ìjọba Ọlọ́run fún àwọn ìlú mìíràn pẹ̀lú, nítorí náà ni a sá ṣe rán mi.”
44 Nake agĩthiĩ na mbere na kũhunjia thĩinĩ wa thunagogi cia Judea.
Ó sì ń wàásù nínú Sinagọgu ti Judea.

< Luka 4 >