< Amosi 6 >
1 Kaĩ mũrĩ na haaro-ĩ! inyuĩ mũikaraga mwĩgangarĩte mũrĩ kũu Zayuni, na inyuĩ mũiguaga mũrĩ agitĩre mũrĩ kĩrĩma-igũrũ gĩa Samaria; o inyuĩ mũrĩ igweta thĩinĩ wa rũrĩrĩ rũrĩa rũrĩ mbere ya iria ingĩ, kũrĩa andũ a Isiraeli mathiiaga.
Ègbé ni fún ẹ̀yin tí ará rọ̀ ní Sioni àti ẹ̀yin tí ẹ wà ní abẹ́ ààbò ní òkè Samaria àti ẹ̀yin olókìkí orílẹ̀-èdè tí ẹ̀yin ènìyàn Israẹli máa ń tọ̀ ọ́ wá.
2 Thiĩi Kaline mũkeyonere kuo, ningĩ muume kuo mũthiĩ nginya Hamathu, itũũra rĩu inene, mũcooke mũikũrũke mũkinye Gathu kwa Afilisti. Anga acio nĩega magakĩra mothamaki manyu meerĩ? Bũrũri wao-rĩ, nĩ mũnene gũkĩra wanyu?
Ẹ lọ Kalne kí ẹ lọ wò ó kí ẹ sí tí ibẹ̀ lọ sí Hamati ìlú ńlá a nì. Kí ẹ sì tún sọ̀kalẹ̀ lọ Gati ní ilẹ̀ Filistini. Ǹjẹ́ wọ́n ha dára ju ìpínlẹ̀ yín méjèèjì lọ? Ǹjẹ́ a ha rí ilẹ̀ tó tóbi ju tiyín lọ bí?
3 Inyuĩ mũtĩĩragia mũthenya wa ũũru, na mũkareharehe wathani wa ũhinya ũkuhĩrĩrie.
Ẹ̀yin sún ọjọ́ ibi síwájú, ẹ sì mú ìjọba òǹrorò súnmọ́ tòsí.
4 Mũkomagĩra marĩrĩ magemetio na mĩguongo, na mũgetambũrũkia itanda-inĩ cianyu. Mũrĩĩaga tũgondu tũrĩa twega mũno, na tũcaũ tũrĩa tũnoru.
Ẹ̀yin sùn lé ibùsùn tí a fi eyín erin ṣe ẹ sì tẹ́ ara sílẹ̀ ni orí àwọn ibùsùn ẹyin pa èyí tí o dára nínú àwọn ọ̀dọ́-àgùntàn yín jẹ ẹ sì ń pa àwọn ọ̀dọ́ màlúù láàrín agbo wọn jẹ.
5 Mũtiindaga mũkĩhũũra inanda cianyu cia mũgeeto o ta Daudi, na mũgethondekera inanda ingĩ cia kũina nacio.
Ẹ̀yin ń lo ohun èlò orin bí i Dafidi ẹ sì ń ṣe àwọn àpilẹ̀rọ àwọn ohun èlò orin.
6 Mũnyuuaga ndibei mbakũri riita, na mũkehakaga maguta marĩa mega mũno, no mũtiiguaga kĩeha nĩ ũndũ wa mwanangĩko wa Jusufu.
Ẹ̀yin mu wáìnì ẹ̀kún ọpọ́n kan àti ìkunra tí o dára jùlọ ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò káàánú ilé Josẹfu tí ó di ahoro.
7 Tondũ ũcio-rĩ, mũgaatuĩka a mbere gũtahwo; ndĩa cianyu na gũikara mwĩtambũrũkĩtie ithire.
Nítorí náà, àwọn ni yóò lọ sí ìgbèkùn pẹ̀lú àwọn tí ó ti kó lọ sí ìgbèkùn àsè àwọn tí ń ṣe àṣelékè ni a ó mú kúrò.
8 Mwathani Jehova nĩehĩtĩte akĩĩgwetaga we mwene, o we Jehova Ngai Mwene-Hinya-Wothe, akoiga atĩrĩ: “Nĩthũire mwĩtĩĩo wa Jakubu, na ngamena ciĩhitho ciake iria nũmu; nĩngarekereria itũũra rĩu inene na kĩrĩa gĩothe kĩrĩ thĩinĩ warĩo kũrĩ thũ.”
Olúwa Olódùmarè ti búra fúnra rẹ̀, Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun sì ti wí pé: “Mo kórìíra ìgbéraga Jakọbu n kò sì ní inú dídùn sí odi alágbára rẹ̀, Èmi yóò sì fa ìlú náà lé wọn lọ́wọ́ àti ohun gbogbo tí ó wà nínú rẹ̀.”
9 Andũ ikũmi mangĩgatigara thĩinĩ wa nyũmba ĩmwe-rĩ, o nao no magaakua.
Bí ọkùnrin mẹ́wàá bá ṣẹ́kù nínú ilé kan, àwọn náà yóò kú.
10 Nake mũndũ wao ũrĩa wa gũcina mĩĩrĩ ĩyo angĩũka kũmiumia nja ya nyũmba na orie mũndũ ũrĩa wĩhithĩte kuo thĩinĩ atĩrĩ, “Kũrĩ mũndũ ũngĩ ũtakuĩte mũrĩ nake?” Nake oige atĩrĩ, “Aca.” Nake acookie oige atĩrĩ, “Kira ki! Tũtikagwete rĩĩtwa rĩa Jehova.”
Bí ẹbí tí ó yẹ kí ó gbé òkú wọn jáde fún sínsin bá wọlé, bí o ba sì béèrè pé ǹjẹ́ ẹnìkan wa tí ó fi ara pamọ́ níbẹ̀, “Ǹjẹ́ ẹnìkankan wà lọ́dọ̀ yín?” tí ó bá sì dáhùn wí pé, “Rárá,” nígbà náà ni yóò wí pé, “Pa ẹnu rẹ mọ́ àwa kò gbọdọ̀ dárúkọ Olúwa.”
11 Nĩgũkorwo Jehova nĩathanĩte, nake nĩagathutha nyũmba ĩrĩa nene ĩtuĩke icunjĩ, na nyũmba ĩrĩa nini ituĩke tũcunjĩ.
Nítorí Olúwa tí pa àṣẹ náà, Òun yóò sì wó ilé ńlá náà lulẹ̀ túútúú, àti àwọn ilé kéékèèké sí wẹ́wẹ́.
12 Kaĩ mbarathi ingĩhota gũtengʼera nyanjara-inĩ cia mahiga? Kũrĩ mũndũ ũngĩrĩma kuo na mũraũ wa ndegwa? No inyuĩ mũgarũrĩte kĩhooto gĩgatuĩka ũrogi, na matunda ma ũthingu magatuĩka ũrũrũ,
Ǹjẹ́ ẹṣin a máa sáré lórí àpáta bí? Ǹjẹ́ ènìyàn a máa fi akọ màlúù kọ ilẹ̀ níbẹ̀? Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti yí òtítọ́ padà sí májèlé ẹ sì ti sọ èso òdodo di ìkorò.
13 inyuĩ arĩa mũkenagĩra ũhootani ũrĩa ũtarĩ ho, na mũkoigaga atĩrĩ, “Githĩ tũtiatunyanire Karinaimu na hinya witũ ithuĩ ene?”
Ẹ̀yin yọ̀ torí ìṣẹ́gun lórí Lo-Debari, ẹ̀yin sì wí pé, “Ṣé kì í ṣe agbára wa ni àwa fi gba Karnaimu?”
14 Nĩgũkorwo Jehova Ngai Mwene-Hinya-Wothe ekuuga atĩrĩ, “Nĩngarahũra rũrĩrĩ rũgũũkĩrĩre, wee nyũmba ya Isiraeli, rũrĩa rũgakũhinyĩrĩria kuuma itoonyero rĩa Hamathu, o nginya mũkuru wa Araba.”
Nítorí Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Èmi yóò gbé orílẹ̀-èdè kan dìde sí ọ ìwọ Israẹli, wọn yóò pọ́n yín lójú ní gbogbo ọ̀nà, láti Lebo-Hamati, títí dé pẹ̀tẹ́lẹ̀ Arabah.”