< Segalaia 7 >

1 Eso biyaduyale amola oubi sesegeyale (Gisilefi oubi) ode biyaduyale Da: liase ea ouligisu amoga, Hina Gode da nama sia: ne iasu i.
Ó sì ṣe ní ọdún kẹrin Dariusi ọba, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ́ Sekariah wá ni ọjọ́ kẹrin oṣù Kisleu tí ń ṣe oṣù kẹsànán.
2 Amo eso galu, Bedele moilai dunu da Sialisa, Ligemelege amola ilia fa: no bobogesu dunu, amo Hina Gode Bagadedafa Ea hahawane dogolegele fidisu adole lama: ne, Ea Debolo diasuga asunasi.
Nígbà tí wọ́n ènìyàn Beteli rán Ṣareseri àti Regemmeleki, àti àwọn ènìyàn wọn sí ilé Ọlọ́run láti wá ojúrere Olúwa.
3 Amola gobele salasu dunu amola balofede dunu ilima amane adole ba: ma: ne, asunasi, “Ninia da Debolo Diasu da mugululi dagoi amo dawa: ma: ne, ode bagohame amoga, oubi biyale huluane amoga dini dawa: lalu. Ninia da amo hou mae fisili, gebewane hamonanoma: bela: ?”
Àti láti bá àwọn àlùfáà tí ó wà ní ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun, àti àwọn wòlíì sọ̀rọ̀ wí pé, “Ṣé kí èmi ó sọkún ní oṣù karùn-ún kí èmi ya ara mi sọ́tọ̀, bí mo ti ń ṣe láti ọdún mélòó wọ̀nyí wá bí?”
4 Goe sia: ne iasu da Hina Gode Ea sia: nama misi.
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tọ̀ mí wá pé,
5 E da amane sia: i, “Isala: ili soge fi dunuma amola gobele salasu dunuma huluane ilima sia: ma. Ilia da ode 70 amoga oubi bi amola fesu amoga ha: i mae nawene didigia: su hamonoba, ilia da Nama nodone sia: ma: ne hame hamoi.
“Sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, àti fún àwọn àlùfáà pé, ‘Nígbà tí ẹ̀yin gbààwẹ̀, tí ẹ sì ṣọ̀fọ̀ ní oṣù karùn-ún àti keje, àní fun àádọ́rin ọdún wọ̀nyí, ǹjẹ́ èmi ni ẹ̀yin ha ń gbààwẹ̀ yín fún?
6 Amola ilia da ha: i maiyaba amola waini maiyaba, ilia da ilisu sadima: ne fawane na: loba.”
Nígbà tí ẹ sì jẹ, àti nígbà tí ẹ mu, fún ara yín kọ́ ni ẹ̀yin jẹ, àti fún ara yín kọ́ ni ẹ̀yin mú bí?
7 Amo sia: Hina Gode da musa: balofede dunu amo ilia lafidili sia: i. Amo esoha Yelusaleme da bagade gaguiwane ba: i, amola dunu bagohame amo ganodini esalebe ba: i. Dunu bagohame da moilai amo Yelusaleme sisiga: i amo ganodini esalebe ba: i. Amola ga (south) soge amola guma: dini agolo soge goumi baiga gala, amo ganodini dunu bagohame esalebe ba: i.
Wọ̀nyí kọ́ ni ọ̀rọ̀ ti Olúwa ti kígbe láti ọ̀dọ̀ àwọn wòlíì ìṣáájú wá, nígbà tí a ń gbé Jerusalẹmu, tí ó sì wà ní àlàáfíà, pẹ̀lú àwọn ìlú rẹ̀ tí ó yí i káàkiri, nígbà tí a ń gbé gúúsù àti pẹ̀tẹ́lẹ̀.’”
8 Hina Gode da amo sia: ne iasu Segalaiama i,
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Sekariah wá, wí pé,
9 “Na da musa: hemonega amo hamoma: ne sia: i Na fi dunuma i, ‘Dilia huluane moloidafa fofada: su hamoma! Amola asigi hou amola gogolema: ne olofosu hou dilia enoma enoma olelema.
“Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, ‘Ṣe ìdájọ́ òtítọ́, kí ẹ sì ṣe àánú àti ìyọ́nú olúkúlùkù sí arákùnrin rẹ̀.
10 Dilia da uda didalo, guluba: mano, ga fi dunu dili bisili esala amola nowa da hahani hame gaguiwane dili bisili esala, amo mae banenesima. Amola dilia dunu eno enoia wadela: lesimusa: mae ilegema. Na da amane sia: i!
Má sì ṣe ni opó lára tàbí aláìní baba, àlejò, tàbí tálákà; kí ẹnikẹ́ni nínú yín má ṣe gbèrò ibi ní ọkàn sí arákùnrin rẹ̀.’
11 Be Na fi dunu da gasa fili, Na sia: nabimu higa: i. Ilia da Na sia: odoga: i.
“Ṣùgbọ́n wọ́n kọ̀ láti gbọ́, wọ́n sì gún èjìká, wọ́n sì pa ẹ̀yìn dà, wọ́n di etí wọn, kí wọn má ba à gbọ́.
12 Ilia da ilila: dogo igi agoane ga: nasima: ne hamoi. Ilia da olelesu amo Na da musa: esalu balofede dunu ilia lafidili olelei, amo nabimu odoga: beba: le, Na da ougi bagade ba: i.
Wọ́n sé ọkàn wọn bí òkúta líle, kí wọn má ba à gbọ́ òfin, àti ọ̀rọ̀ tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti fi ẹ̀mí rẹ̀ rán nípa ọwọ́ àwọn wòlíì ìṣáájú wá. Ìbínú ńlá sì dé láti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
13 Na da sia: noba, ilia da hame nababeba: le, ilia da Nama sia: ne gadoloba, Na amola da ilia sia: ne gadosu hame nabi.
“‘Ó sì ṣe, gẹ́gẹ́ bí ó ti kígbe, tí wọn kò sì fẹ́ gbọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n kígbe, tí èmi kò sì fẹ́ gbọ́,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
14 Na da mulu agoane, ili doa: le fasili, ga fi soge ganodini esaloma: ne, sefasi dagoi. Amola Na soge noga: idafa da bu wadela: i dunu hame esalebe soge hamoi dagoi.
‘Mo sì fi ìjì tú wọn ká sí gbogbo orílẹ̀-èdè tí wọn kò mọ̀. Ilẹ̀ náà sì dahoro lẹ́yìn wọn, tí ẹnikẹ́ni kò là á kọjá tàbí kí ó padà bọ̀, wọ́n sì sọ ilẹ̀ ààyò náà dahoro.’”

< Segalaia 7 >