< Ha:ga:iai 1 >

1 Be ode ageyadu amoga, Da: liase da Besia soge amo hina bagade hamone ouligi esalu, amola oubi gafe amoga eso agega, Hina Gode da Ha: ga: iai ema sia: sia: i. Amola Ha: ga: iai da alofele, amo sia: Yuda eagene ouligisu dunu amola Selababele (Sia: lediele egefe) amola gobele salasu ouligisu dunu Yosiua (Yihosada: ge egefe), ilima bu sia: i.
Ní ọdún kejì ọba Dariusi ní ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kẹfà, ọ̀rọ̀ Olúwa wá nípasẹ̀ wòlíì Hagai sí Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, baálẹ̀ Juda, àti sọ́dọ̀ Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà.
2 Hina Gode Bagadedafa da Ha: ga: iaima amane sia: i, “Isala: ili dunu ilia da amane sia: sa, ‘Debolo Diasu bu gagumu esodafa da hame doaga: i.’”
Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Àwọn ènìyàn wọ̀nyí wí pé, ‘Kò tí ì tó àkókò láti kọ́ ilé Olúwa.’”
3 Amalalu, Hina Gode Ea sia: amo da dunu huluane ilia nabima: ne, balofede dunu Ha: ga: iaima sia: ne i.
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa wá láti ọ̀dọ̀ wòlíì Hagai wí pé,
4 Hina Gode da amane sia: i, “Na dunu fi abuliba: le ilila: diasu amo noga: le gaguli esala, amola Na Sia: ne Gadosu Diasu amo bu wadela: lesi dagoi ba: sala: ?
“Ǹjẹ́ àkókò ni fún ẹ̀yin fúnra yín láti máa gbé ní ilé tí a ṣe ní ọ̀ṣọ́ nígbà tí ilé yìí wà ni ahoro?”
5 Dilia da abuliba: le dilima hou doaga: ga: lalebe amo hame ba: sala: ?
Nísìnsinyìí, èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Ẹ kíyèsi ọ̀nà yín.
6 Dilia da gagoma bagade sagai galu, be amomane bagade hame fai. Dilia da ha: i manu gala be dili sadini manu defele hame gala. Dilia da waini hano manu gala, be dilia da waini hano hanai gumimu defele hame gala. Dilia da abula gala, be bagahameba: le, dilia da: i hame hougala: sa. Dunu da muni lamusa: hawa: hamosa, be amomane esaloma: ne lamu liligi amo defele hame ba: sa.
Ẹ̀yin ti gbìn ohun ti ó pọ̀. Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kórè díẹ̀ níbẹ̀. Ẹ̀yin jẹun, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò yó. Ẹ̀yin mu ṣùgbọ́n kò tẹ́ ẹ yín lọ́run; ẹ̀yin wọ aṣọ, ṣùgbọ́n kò mú òtútù yin lọ; ẹyin gba owó iṣẹ́ ṣùgbọ́n ẹ ń gbà á sínú ajádìí àpò.”
7 Di da abuliba: le, amo hou doaga: be hame ba: bela: ?
Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Ẹ kíyèsi ọ̀nà yín.
8 Defea, wahadafa agoloba: le heda: le, diasu gagusu ifa lidima, amola Na Debolo Diasu mugului amo bu buga: le gaguma. Amasea Na da dilima nodomu amola dilia da Nama defele nodone sia: ne gadomu.
Ẹ gun orí àwọn òkè ńlá lọ, kí ẹ sì mú igi wá pẹ̀lú yín. Kí ẹ sì kọ́ ilé náà, kí inú mi bà le è dùn sí i, kí a sì yín mí lógo,” ni Olúwa wí.
9 Dilia da ifabi ganodini ha: i manu bagade lamusa: dawa: i galu. Amomane ha: i manu da dadamini aguni manoba, Na da amo dadami fulabole fasi dagoi. Abuliba: le, Na agoane hamobela: ? Bai Na Debolo Diasu da mugululi sia: i dagoiba: le. Be dilia da mae dawa: le, dilia diasu fawane gagulala.
“Ẹyin ti ń retí ọ̀pọ̀, ṣùgbọ́n kíyèsi i, o yípadà sí díẹ̀. Ohun tí ẹ̀yin mú wa ilé, èmi sì fẹ́ ẹ dànù. Nítorí kí ni?” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. “Nítorí ilé mi tí ó dahoro; tí olúkúlùkù yín sì ń sáré fún ilé ara rẹ̀.
10 Amaiba: le, Na da diligili gibu amola ha: i manu hame iaha.
Nítorí yín ni àwọn ọ̀run ṣe dá ìrì dúró tí ilẹ̀ sì kọ̀ láti mu èso jáde.
11 Na da dilia sogega esoi bagade i dagoi. Dilia soge agolo, gagoma sagai, waini sagai, olefe ifa sagai, dilia sagai liligi huluane amola dunu fi amola ohe fi huluane amo da esoi bagade ba: sa.
Mo sì ti pe ọ̀dá sórí ilẹ̀ àti sórí àwọn òkè ńlá, sórí ọkà àti sórí wáìnì tuntun, sórí òróró àti sórí ohun ti ilẹ̀ ń mú jáde, sórí ènìyàn, sórí ẹran àti sórí gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín.”
12 Amalalu, Selababele, Yosiua amola dunu fi huluane (amo da Ba: bilone mugului asili buhagi), ilia Hina Gode Ea hamoma: ne sia: i defele hamoi. Ilia da beda: ne, balofede dunu Ha: ga: iai (Hina Gode Ea Sia: Alofesu dunu) amo ea sia: nabawane hamoi.
Nígbà náà ni Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà pẹ̀lú gbogbo ènìyàn ìyókù, gba ohùn Olúwa Ọlọ́run wọn gbọ́ àti ọ̀rọ̀ wòlíì Hagai, nítorí Olúwa Ọlọ́run ni ó rán an. Àwọn ènìyàn sì bẹ̀rù Olúwa.
13 Amalalu, Ha: ga: iai da Hina Gode Ea sia: amo Isala: ili dunuma alofele adoi, amane, “Na da dafawane ilegesa. Na da dili hamedafa yolesimu.”
Nígbà náà ni Hagai ìránṣẹ́ Olúwa ń jíṣẹ́ Olúwa fún àwọn ènìyàn pé, “Èmí wà pẹ̀lú yín,” ni Olúwa wí.
14 Hina Gode da Selababele, Yuda eagene ouligisu dunu, gobele salasu ouligisu dunu Yosiua amola dunu huluane amo da mugululi asili buhagi, amo ilia da Debolo Diasu bu gaguma: ne, Hina Gode da ilia a: silibu denesi dagoi. Ilia da ilia Hina Gode Bagadedafa Ea Debolo Diasu gaguma: ne, hawa: hamosu mui.
Nítorí náà, Olúwa ru ẹ̀mí Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli sókè, baálẹ̀ Juda àti ẹ̀mí Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà àti ẹ̀mí gbogbo ènìyàn ìyókù. Wọ́n sì wá, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣiṣẹ́ lórí ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run wọn,
15 Ilia da oubi gafeale amola eso 24 amo Da: liase ea hina bagade ouligisu eso amoga, amo hawa: hamosu mui.
ní ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹfà ní ọdún kejì ọba Dariusi.

< Ha:ga:iai 1 >