< Bisisu 18 >

1 Amo esoha, hina bagade dunu Isala: ili soge ganodini esalebe hame ba: i. Isala: ili fi dunu da ilia soge ilegei amo lai dagoi. Be Da: ne fi da soge hame lai. Amaiba: le, ilia da soge gesowale fima: ne hogoi helesu.
Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àwọn ọmọ Israẹli kò ní ọba. Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àwọn ẹ̀yà Dani ń wá ilẹ̀ tiwọn, níbi tí wọn yóò máa gbé, nítorí pé títí di àkókò náà wọn kò ì tí ì pín ogún ilẹ̀ fún wọn ní ìní láàrín àwọn ọmọ Israẹli.
2 Da: ne dunu da ilia sosogo fi amoga bagade dawa: su dunu biyale gala amo soge hogomusa: ilegei. Ilia da amo dunu, Soula moilai bai bagade amola Esadoule soge, amoga asunasi. Ilia da Ifala: ime agolo sogega doaga: loba, Maiga ea diasuga golai.
Nítorí náà àwọn ẹ̀yà Dani rán àwọn jagunjagun márùn-ún lọ láti Sora àti Eṣtaoli láti yọ́ ilẹ̀ náà wò àti láti rìn ín wò. Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ṣe ojú fún gbogbo àwọn ẹ̀yà wọn. Wọ́n wí fún wọn pé, “Ẹ lọ kí ẹ rin ilẹ̀ náà ká, kí ẹ sì wò ó fínní fínní.” Àwọn ọkùnrin náà wọ àwọn ìlú tí ó wà ní agbègbè òkè Efraimu, wọ́n sì dé ilé Mika, níbi tí wọ́n sùn ní òru náà.
3 Amoga esalea, ilia da gobele salasu ayeligi ea sia: hisu nababeba: le, e da Lifai dunu ilia dawa: i galu. Ilia da ema asili, amane adole ba: i, “Di da guiguda: adi hamosala: ? Nowa da di guiguda: oule misibala: ?”
Nígbà tí wọ́n súnmọ́ tòsí ilé e Mika, wọ́n dá ohùn ọ̀dọ́mọkùnrin Lefi náà mọ̀, torí náà wọ́n yípadà, wọ́n sì wọ inú ilé náà lọ wọ́n sì bi í pé, “Tá ni ó mú ọ wa sí ibi? Kí ni ìwọ ń ṣe níhìn-ín yìí? Èéṣe tí o fi wà ní ibí?”
4 E bu adole i, “Na da Maiga ea hawa: hamonana. Na da ea gobele salasu hawa: hamonanebeba: le, e da nama bidi iaha.”
Ó sọ ohun tí Mika ti ṣe fún un, ó fi kún un fún wọn pé, “Ó gbà mí sí iṣẹ́, èmi sì ni àlùfáà rẹ̀.”
5 Ilia da ema bu adole i, amane, “Di Godema adole ba: ma. Ninia da logoga ahoasea, hahawane ba: ma: bela: ?”
Wọ́n wí fún un pé, “Jọ̀wọ́ béèrè ní ọwọ́ Ọlọ́run, kí àwa lè mọ̀ bí ìrìnàjò wa yóò yọrí sí rere.”
6 Gobele salasu dunu da ilima bu adole i, “Mae dawa: ma! Dilia da se hame nabimu. Dilia ahoasea, Hina Gode da dili noga: le ouligilalumu.”
Àlùfáà náà dá wọn lóhùn pé, “Ẹ máa lọ ní àlàáfíà. Ìrìnàjò yín tí ẹ̀yin ń rìn bá ojúrere Olúwa pàdé.”
7 Amaiba: le, amo dunu biyale gala da fisili, asili, La: isi moilaiga doaga: i. Ilia da La: isi dunu ilia hou ba: i. Ilia da Saidounia dunu defele, hahawane, olofoiwane esalu. Ilia hanai huluane, ilia da gagui dagoi. Ilia da eno dunuma hame gegenai. Ilia da Saidounia dunu gadenene hame esalu. Ilia da eno dunu fi ilima hame gilisisu.
Àwọn ọkùnrin márààrún náà kúrò, wọ́n sì wá sí Laiṣi, níbi tí wọ́n ti rí i pé àwọn ènìyàn tí ń gbé ibẹ̀ ní ààbò, bí àwọn ará Sidoni, láìsí ìfòyà àti ní ìpamọ́. Ní ìgbà tí ilẹ̀ wọn kò ṣe aláìní ohunkóhun, wọ́n ní ọrọ̀ púpọ̀. Ibùgbé wọn tún jìnnà sí ti àwọn ará Sidoni, wọn kò fi ohunkóhun bá ẹnikẹ́ni dàpọ̀.
8 Dunu biyale gala da ilia moilaidafa amo Soula amola Esedoule amoga bu doaga: loba, ilia fi dunu da ilia ba: i liligi ilima adoma: ne sia: i.
Nígbà tí wọ́n padà sí Sora àti Eṣtaoli, àwọn arákùnrin wọn bi wọ́n léèrè pé, “Báwo ni ibi tí ẹ lọ ti rí? Kí ni ìròyìn tí ẹ mú wá?”
9 Ilia da bu adole i, “Misa! Ninia La: isi moilai fi doagala: mu da defea. Ninia da ilia soge ba: i dagoi. Soge da noga: idafa. Dilia! Udigili mae esaloma! Hedolo! Amoga asili, amo soge gesowale fima.
Wọ́n dáhùn pé, “Ẹ dìde ẹ jẹ́ kí a lọ kọlù wọ́n! A wá rí i pé ilẹ̀ náà dára gidigidi. Ṣé ẹ̀yin ó sì jókòó láìsí nǹkan nípa rẹ̀? Ẹ má ṣe lọ́ra láti lọ síbẹ̀ kí ẹ sì gba ilẹ̀ náà.
10 Amoga asili dilia da ba: mu. Dunu eno da ilima doagala: mu ilia hame dawa: Soge da bagadedafa. Amo ganodini da dilia hanai huluane ba: mu. Gode da amo soge dilima i dagoi.”
Nígbà tí ẹ̀yin bá dé ibẹ̀, ẹ yóò rí àwọn ènìyàn tí ọkàn wọn balẹ̀ àti ilẹ̀ tí ó tẹ́jú tí Ọlọ́run ti fi fún yín, ilẹ̀ tí kò ṣe aláìní nǹkan kan.”
11 Amaiba: le, Da: ne fi dunu 600 da gegema: ne momagele, Soula amola Esedoule fisili asi.
Nígbà náà ni ẹgbẹ̀ta ọkùnrin tí ó múra ogun láti ìran Dani, jáde lọ láti Sora àti Eṣtaoli ní mímú ra láti jagun.
12 Ilia da sogebi amo Gilia: de Yialimi moilai bai bagade Yuda soge ganodini amo ea eso dabe la: ididili amoga abula diasu gaguli esalu. Amaiba: le, amo sogebi ea dio wali da Da: ne Abula Fisisu.
Wọ́n sì jáde lọ, ní ojú ọ̀nà wọn, wọ́n tẹ̀dó ogun sí ẹ̀bá Kiriati-Jearimu ní Juda. Ìdí nìyí tí wọ́n fi ń gbé ìwọ̀-oòrùn Kiriati-Jearimu ni Mahane-Dani títí di òní yìí.
13 Amo sogebi fisili asili, ilia da Maiga ea diasu Ifala: ime agolo soge ganodini gala, amoga doaga: i.
Láti ibẹ̀ wọ́n kọjá lọ sí àwọn ìlú agbègbè òkè Efraimu, wọ́n sì dé ilé Mika.
14 Amalalu, dunu biyale gala musa: da La: isi soge hogola asi, ilia dogolegei dunuma amane sia: i, “Diasu afae guiguda: da ifaga hamoi ‘gode’ agoaila amo silifaga dedeboi, amo dilia dawa: bela: ? ‘gode’ agoaila eno amola gala amola ‘ifode’ gala. Ninia da adi hamoma: bela: ?”
Nígbà náà ni àwọn ọkùnrin márùn-ún tí ó lọ yọ́ ilẹ̀ Laiṣi wò sọ fún àwọn arákùnrin wọn pé, “Ǹjẹ́ ẹ̀yin mọ̀ pé ọ̀kan nínú àwọn ilé yìí ní ẹ̀wù efodu, àwọn yòókù ní òrìṣà, ère gbígbẹ́ àti ère dídà? Ẹ mọ ohun tí ó yẹ kí ẹ ṣe báyìí.”
15 Amaiba: le, ilia da Lifai ayeligi ea esalebe Maiga diasu ganodini asili, Lifai ea hou ema adole ba: i.
Wọ́n sì yà sí ibẹ̀, wọ́n sì wọ ilé ọ̀dọ́mọkùnrin Lefi náà, sí ilé Mika, wọ́n sì béèrè àlàáfíà rẹ̀.
16 Amoha, Da: ne dadi gagui 600, gegemusa: momagei dagoi, da diasu gagoi ga: suga lelebe ba: i.
Àwọn ẹgbẹ̀ta ọkùnrin ará Dani náà tí ó hámọ́ra ogun, dúró ní àbáwọlé ẹnu odi.
17 Desega ahoasu dunu biyale gala da diasu ganodini golili sa: ili, ilia da ifa ‘gode’ agoaila silifaga dedeboi, amola ‘gode’ agoaila eno huluane amola “ifode” lai dagoi. Lifai gobele salasu dunu amola dadi gagui dunu 600 agoane da logo holei gadenene lelu.
Àwọn ọkùnrin márùn-ún tí wọ́n lọ yọ́ ilẹ̀ náà wò wọlé lọ wọ́n sì kó ère gbígbẹ́ náà, efodu náà, àwọn òrìṣà ìdílé àti ère dídà náà nígbà tí àlùfáà náà àti àwọn ẹgbẹ̀ta ọkùnrin tí ó hámọ́ra ogun dúró ní à bá wọ ẹnu odi náà.
18 Dunu da Maiga diasuga, sema liligi wamolamusa: ahoanoba, gobele salasu dunu da ilima amane adole ba: i, “Dilia da adi hamosala: ?”
Nígbà tí àwọn ọkùnrin yìí wọ ilé e Mika lọ tí wọ́n sì kó ère fínfín náà, efodu náà, àwọn òrìṣà ìdílé mìíràn àti ère dídà náà, àlùfáà náà béèrè lọ́wọ́ wọn wí pé, “Kí ni ẹ̀yin ń ṣe?”
19 Ilia bu adole i, “Ouiya: ma! Maedafa sia: ma! Di amola nini sigi masa! Di da ninia gobele salasu dunu hamomu da defea. Di da dunu afae ea sosogo fi fonobahadi ilima gobele salasu hawa: hamomu da defea hame. Be di da Isala: ili fidafa bagade huluane ilima gobele salasu hawa: hamomu da defea.”
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Dákẹ́! Ma sọ nǹkan kan, tẹ̀lé wa kí o sì di baba àti àlùfáà wa. Kò ha sàn fún ọ láti máa ṣe ìránṣẹ́ ẹ̀yà àti ìdílé kan tí ó wá láti Israẹli bí àlùfáà ju ilé ẹnìkan ṣoṣo lọ?”
20 Amo hou, gobele salasu dunu da hahawane ba: i. Amaiba: le, e da sema liligi huluane gaguli, ili sigi asi.
Nígbà náà ni inú àlùfáà náà sì dùn, òun mú efodu náà, àwọn òrìṣà ìdílé mìíràn àti ère fínfín náà, ó sì bá àwọn ènìyàn náà lọ.
21 Ilia sinidigili, logoga asi. Ilia mano, bulamagau amola liligi da ili bisili asi.
Wọ́n kó àwọn ọmọdé wọn, àwọn ohun ọ̀sìn wọn àti gbogbo ohun ìní wọn síwájú, wọ́n yípadà wọ́n sì lọ.
22 Ilia da fonobahadi sedade asili, Maiga da ea gadenene fi dunu huluane amo dunuma gegemusa: fa: no bobogei. Ilia da Da: ne dunuma doaga: le,
Nígbà tí wọ́n ti rìn jìnnà díẹ̀ sí ilé Mika, àwọn ọkùnrin tí ó wà ní agbègbè Mika kó ara wọn jọ, wọ́n sì lé àwọn ará Dani bá.
23 ilima wele sia: i dagoi. Da: ne dunu da sinidigili, Maiga ema amane adole ba: i, “Adi hou? Dunu bagade da abuli misibala: ?”
Bí wọ́n ṣe ń pariwo tẹ̀lé wọn lẹ́yìn, àwọn ará Dani yípadà wọ́n sì bi Mika pé, “Kí ló ṣe ọ́ tí o fi pe àwọn ọkùnrin rẹ jáde láti jà?”
24 Maiga da bu adole i, “Giadofai dilia dawa: Dilia da na gobele salasu dunu amola ‘gode’ liligi na hamoi amo huluane lale, asi dagoi. Na da liligi eno hame galebe.”
Ó dáhùn pé, “Ẹ̀yin kó àwọn ère tí mo ṣe, àti àlùfáà mi lọ. Kí ni ó kù tí mo ní? Báwo ni ẹ̀yin ò ṣe béèrè pé, ‘Kí ló ṣe ọ́?’”
25 Da: ne dunu da ema bu adole i, “Di da ouiya: mu da defea. Bai agoane hame hamosea, ninia dunu da di doagala: mu. Amasea, di amola dia sosogo fi huluane da bogogia: mu.”
Àwọn ọkùnrin Dani náà dáhùn pé, “Má ṣe bá wa jiyàn, tàbí àwọn oníbìínú fùfù ènìyàn lè kọlù yín, ìwọ àti àwọn ìdílé yóò sì sọ ẹ̀mí yín nù.”
26 Amalalu, Da: ne dunu da bu logoga ahoanu. Maiga da ba: i dagoi, ilia gasa da ea gasa baligi dagoi. Amaiba: le, e da sinidigili, hi diasuga buhagi.
Àwọn ọkùnrin Dani náà sì bá ọ̀nà wọn lọ. Nígbà tí Mika rí í pé wọ́n lágbára púpọ̀ fún òun, ó sì padà sí ilé rẹ̀.
Wọ́n sì kó àwọn ohun tí Mika ti ṣe àti àlùfáà rẹ̀, wọ́n sì kọjá lọ sí Laiṣi, ní ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn tí ó ní ìbàlẹ̀ ọkàn tí wọ́n sì wà ní àlàáfíà. Wọ́n fi ojú idà kọlù wọ́n, wọ́n sì jó ìlú wọn run.
28 Da: ne dunu da gobele salasu dunu amola Maiga ea hamoi liligi huluane lalu, asili, La: isi moilai doagala: i. La: isi dunu da olofoiwane, asaboiwane noga: i dunu esalu. Ilia da fago amo ganodini esalu. Amo fago ganodini moilai eno galu amo Bedelihobe. Da: ne dunu da La: isi dunu, uda amola mano huluane medole legei. Ilia diasu huluane ilia da laluga ulagisi. La: isi dunu da gaga: su dunu hame ba: i. Bai ilia da Saidone sogega sedagawane esalu amola ilia eno dunu fi ilima hame gilisisu. Da: ne dunu da La: isi moilai bu gaguli, amo ganodini fi.
Kò sì sí ẹnikẹ́ni tí yóò gbà wọ́n sílẹ̀ nítorí pé ibi tí wọ́n ń gbé jìnà sí àwọn ará Sidoni, wọn kò sì ní àṣepọ̀ pẹ̀lú ẹnikẹ́ni. Ìlú náà wà ní inú àfonífojì lẹ́bàá a Beti-Rehobu. Àwọn ará Dani sì tún ìlú náà kọ́, wọ́n sì ń gbé inú rẹ̀.
29 Amo moilai dio La: isi ilia da fisili bu Da: ne dio asuli. Ilia siba eda Da: ne amo Ya: igobe ea mano, amo dawa: le ilia amo dio asuli.
Wọ́n sọ orúkọ ìlú náà ní Dani gẹ́gẹ́ bí orúkọ baba ńlá wọn Dani, ẹni tí wọ́n bí fún Israẹli: bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Laiṣi ni orúkọ ìlú náà tẹ́lẹ̀ rí.
30 Da: ne dunu da moilai ganodini ogogosu ‘gode’ ilia lai amoma nodone sia: ne gadomusa: bugisi. Yonada: ne (Gesiome egefe amola Mousese ea aowa) da Da: ne fi amo ganodini gobele salasu hawa: hamosu. Egaga fi amola da e bagia amo hawa: hamonanu. Yuda dunu huluane da mugululi asi dagoiba: le fawane fisi.
Àwọn ọmọ Dani sì gbé àwọn ère kalẹ̀ fún ara wọn níbẹ̀; Jonatani ọmọ Gerṣomu, ọmọ Mose, àti àwọn ọmọ rẹ̀ ni àlùfáà fún àwọn ẹ̀yà Dani títí di àkókò tí a kó ilẹ̀ náà ní ìgbèkùn.
31 Isala: ili dunu da Abula Diasu Siailou sogebiga gagui amoga Godema nodone sia: ne gadosu. Be amo Abula Diasu da dialea, Maiga ea ogogosu ‘gode’ da Da: ne moilai ganodini dialebe ba: i.
Wọ́n tẹ̀síwájú láti lo àwọn ère tí Mika ṣe, ní gbogbo àkókò tí ilé Ọlọ́run wà ní Ṣilo.

< Bisisu 18 >