< Bisisu 17 >

1 Eso afaega Ifala: ime agolo soge ganodini, dunu afae ea dio amo Maiga esalu.
Nígbà náà ni ọkùnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika láti agbègbè òkè Efraimu
2 Maiga da ea amema amane sia: i, “Musa: dunu afae da dima silifa fage 1,100 wamolaloba, di da amo dunuma gagabusu aligima: ne ilegei. Amo na da nabi. Be wali, di ba: ma. Na da amo muni gagusa. Amo wamolasu dunu da na.” Ea ame da amane sia: i, “Nagofe! Hina Gode da dima hahawane dogolegele hamomu da defea.”
sọ fún ìyá rẹ̀ pé, “Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀fà ṣékélì fàdákà èyí tí wọ́n jí mọ́ ọ lọ́wọ́, àti nípa èyí tí mo gbọ́ tí ìwọ ń ṣẹ́ èpè. Kíyèsi fàdákà náà wà ní ọ̀dọ̀ mi, èmi ni mo kó o.” Nígbà náà ni ìyá rẹ̀ dáhùn pé, “Kí Olúwa bùkún ọ ọmọ mi!”
3 E da amo muni ea amema bu i. Ea ame da amane sia: i, “Amo gagabusu aligima: ne da na mano ema doaga: sa: besa: le, na da amo silifa Hina Godema imunu. Amoga ninia da ifa ‘gode’ hamone, silifa amoga dedebomu. Na da amo silifa dima bu iaha.”
Nígbà tí ó da ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀fà ṣékélì fàdákà náà padà fún ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ dáhùn pé, “Èmi ti fi òtítọ́ inú ya sílífà náà sọ́tọ̀ sí Olúwa fún ọmọ mi láti fi dá ère dídá àti ère gbígbẹ́. Èmi yóò dá a padà fún ọ.”
4 Amalalu, e da ea amema bu i. Ea ame da silifa fage 200 amo lale, gula hahamosu dunuma i. E da ifa amo osole dedene, ogogosu loboga hamoi ‘gode’ hamone, silifa amoga dedeboi. Ilia da amo loboga hamoi liligi Maiga ea diasu ganodini ligisi.
Nítorí náà òun dá sílífà náà padà fún ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ sì mú igba ṣékélì fàdákà, ó sì fún alágbẹ̀dẹ fàdákà ẹni tí ó fi wọ́n rọ ère fínfín àti ère dídà. Wọ́n sì kó wọn sí ilé Mika.
5 Amo dunu Maiga da hi sia: ne gadosu diasu gagui galu. E da loboga hamoi ‘gode’ eno amola “ifode” (gobele salasu dunu ea da: i salasu) hamone, ea dunu mano afae amo gobele salasu hawa: hamoma: ne ilegei.
Ọkùnrin náà, Mika sì ní ojúbọ kan. Òun sì ra ẹ̀wù efodu kan, ó sì ṣe àwọn ère kan, ó sì fi ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin ṣe àlùfáà rẹ̀.
6 Amo esoga, hina bagade dunu da Isala: ili soge ganodini hame esalu. Dunu huluane da afae afae hi hanaiga fawane hamosu.
Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ọmọ Israẹli kò ní ọba; olúkúlùkù ṣe bí ó ti rò pé ó tọ́ ní ojú ara rẹ́.
7 Amo esoha, Lifai fi ayeligi afae da Bedeleheme moilai Yuda soge ganodini esalu.
Ọ̀dọ́mọkùnrin kan sì ti Bẹtilẹhẹmu ti Juda wá, tí í ṣe ìdílé Juda, ẹni tí í ṣe ẹ̀yà Lefi, òun sì ṣe àtìpó níbẹ̀,
8 E da Bedeleheme fisili, fimu soge hogomusa: asi. E da ahoanoba, Maiga ea diasu Ifala: ime agolo soge ganodini galu, amoga doaga: i.
ọkùnrin náà sì ti ìlú Bẹtilẹhẹmu ti Juda lọ, láti ṣe àtìpó ní ibikíbi tí ó bá rí. Ní ojú ọ̀nà àjò rẹ̀, ó dé ilẹ̀ Mika nínú àwọn ilẹ̀ òkè Efraimu.
9 Maiga da ema amane adole ba: i, “Di da habidili misibala: ?” E bu adole i, “Na da Lifai fi dunu. Na da Bedeleheme moilai Yuda soge ganodini amoga esalu. Na da fimu sogebi hogosa.”
Mika bi í pé, “Níbo ni ó ti ń bọ̀?” Ó dáhùn pé, “Ọmọ Lefi ni mí láti Bẹtilẹhẹmu Juda, mo sì ń wá ibi tí èmi yóò máa gbé.”
10 Maiga da ema amane sia: i, “Na sigi esaloma! Di da na fidisu dunu amola gobele salasu dunu esalumu da defea. Na da dima silifa fage nabuane gala amola dia abula amola ha: i manu imunu.”
Mika sì sọ fún un wí pé, “Dúró lọ́dọ̀ mi kí ìwọ sì jẹ́ baba mi àti àlùfáà fún mi, èmi ó sì máa fún ọ ní ṣékélì mẹ́wàá fàdákà ní ọdọọdún, pẹ̀lú aṣọ àti oúnjẹ rẹ̀.”
11 Lifai ayeligi da Maigama esaloma: ne sia: i. E da egefe agoane hamosu.
Ọmọ Lefi náà sì gbà láti máa bá a gbé, ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì dàbí ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀.
12 Maiga da ema gobele salasu hawa: hamosu ilegei amola e da Maiga ea diasu ganodini esalu.
Nígbà náà ni Mika ya ará Lefi náà sí mímọ́, ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì di àlùfáà rẹ̀, ó sì ń gbé ilé rẹ̀.
13 Maiga da amane sia: i, “Defea! Wali Lifai dunu da na gobele salasu dunu esala. Amaiba: le, na dawa: ! Hina Gode da na hou amola na liligi huluane hahawane dogolegele hahamomu.”
Mika sì wí pé, “Báyìí, èmi mọ̀ pé Olúwa yóò ṣe mi ní oore nítorí pé mo ní ọmọ Lefi ní àlùfáà mi.”

< Bisisu 17 >