< Yelemaia 40 >

1 Ba: bilone dunu da na amola Yelusaleme dunu amola Yuda fi dunu huluane (amo ilia da Ba: bilone sogega udigili hawa: hamomusa: oule ahoasu) nini huluane sia: inega la: gili, La: ima moilaiga oule asi. Amogawi, Ba: bilone dadi gagui ouligisudafa amo Nebiusala: ida: ne, e da na sia: ine fadegale, na hahawane masa: ne sia: i. Amalalu, Hina Gode da nama sia: i.
Ọ̀rọ̀ náà sì tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa lẹ́yìn tí Nebusaradani balógun àwọn ẹ̀ṣọ́ ti tú u sílẹ̀ ní Rama. Ó rí Jeremiah tí a fi ẹ̀wọ̀n dè láàrín gbogbo àwọn tí wọ́n mú ní Jerusalẹmu àti Juda. Wọ́n kó lọ sí ilẹ̀ àjèjì Babeli.
2 Ba: bilone dadi gagui ouligisudafa da na la: idili oule asili, nama amane sia: i “Dia Hina Gode da amo soge wadela: lesima: ne sia: i.
Nígbà tí balógun ẹ̀ṣọ́ rí Jeremiah, ó sọ fún un wí pé, “Olúwa Ọlọ́run rẹ ni ó pàṣẹ ibí yìí fún mi.
3 Amola wali amo hou E da magagili ilegei, E da hamoi dagoi. Dia fi dunu da Hina Godema wadela: le hamobeba: le amola Ea sia: hame nababeba: le, amo hou da doaga: i dagoi.
Nísinsin yìí, Olúwa ti mú un jáde; ó ti ṣe gẹ́gẹ́ bí ó ti sọ pé òun yóò ṣe. Gbogbo èyí ṣẹlẹ̀ nítorí wí pé ẹ̀yin ènìyàn ṣẹ̀ sí Olúwa, àti pé ẹ kò gbọ́rọ̀ sí àṣẹ rẹ̀.
4 Wali di udigili masa: ne amo sia: ine dia fesua la: gi amo na da fadegala. Di da Ba: bilone sogega na sigi masusa: dawa: sea, defea, misa. Amasea, na da di ouligimu. Be dia amoga masunu higasea, guiguda: esaloma. Difa! Dia hanaiga hamoma!”
Ṣùgbọ́n, ní òní yìí mò ń tú ọ sílẹ̀ kúrò nínú ẹ̀wọ̀n tí ó wà ní ọwọ́ rẹ. Bí o bá fẹ́, tẹ̀lé mi ká lọ sí Babeli, èmi yóò sì bojútó ọ; ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá fẹ́, dúró síbí. Wò ó, gbogbo orílẹ̀-èdè wà níwájú rẹ, lọ sí ibikíbi tí ó bá tẹ́ ọ lọ́rùn.”
5 Na da bu hame adole iabeba: le, Nebiusala: ida: ne da amane sia: i, “Ba: bilone hina bagade da Gedalaia (Ahaiga: me egefe amola Sia: ifa: ne ea aowa) amo Yuda moilai ouligima: ne ilegei dagoi. Di Gedalaiama buhagima. Di da ea diasuga esalumu da defea. O dia hanaiga fawane ahoanoma.” Amalalu, e da nama hahawane iasu i. Amola ha: i manu ianu, na masa: ne logo doasi.
Ẹ̀wẹ̀, kí ó tó di pé Jeremiah pẹ̀yìndà láti máa lọ, Nebusaradani fi kún un wí pé, “Padà tọ Gedaliah ọmọ Ahikamu lọ, ọmọ Ṣafani, ẹni tí ọba Babeli ti fi jẹ baálẹ̀ lórí ìlú Juda, kí o sì máa gbé ní àárín àwọn ènìyàn wọ̀nyí tàbí kí o máa lọ ibikíbi tí ó bá tọ́ ní ojú rẹ.” Nígbà náà ni balógun náà fún un ní oúnjẹ àti ẹ̀bùn, ó sì jẹ́ kí ó lọ.
6 Na da Misiba moilai, Gedalaia ea diasuga esalomusa: asi. Amola na da dunu fi hame mugululi asi soge ganodini esala, ilima gilisili esalu.
Báyìí ni Jeremiah lọ sí ọ̀dọ̀ Gedaliah ọmọkùnrin Ahikamu ní Mispa, ó sì dúró tì í láàrín àwọn ènìyàn tí ó ṣẹ́kù ní ilẹ̀ náà.
7 Yuda dadi gagui ouligisu mogili, amola dadi gagui dunu mogili, da Ba: bilone dunu ili gagulaligimusa: hame asi. Ilia da nabi amo Ba: bilone hina bagade da Gedalaia, Yuda soge amola hame gagui dunu huluane amo da Ba: bilone sogega hame mugululi asi, ilima ouligima: ne ilegei dagoi.
Nígbà tí gbogbo àwọn olórí ogun àti àwọn ènìyàn tí wọ́n kù lórí orílẹ̀-èdè náà gbọ́ pé ọba Babeli ti yan Gedaliah ọmọkùnrin Ahikamu gẹ́gẹ́ bí baálẹ̀ ní ilẹ̀ náà; àti pé ó ti fi àwọn ọkùnrin, obìnrin àti ọmọdé tí wọ́n jẹ́ tálákà ní ilẹ̀ náà tí wọn kò kó lọ sí ilẹ̀ àjèjì sí ìkáwọ́ rẹ̀,
8 Amaiba: le, Isama: iele (Nedanaia egefe) amola Youha: ina: ne (Galia egefe) amola Sila: ia (Da: nahiumede egefe) amola Ifai (Nidoufa dunu) egefelali, amola Ya: ia: sanaia (Ma: iaga soge dunu) amola ilima fa: no bobogesu dunu da Misiba moilaiga Gedalaia ba: musa: asi.
wọ́n wá sí ọ̀dọ̀ Gedaliah ní Mispa; Iṣmaeli ọmọkùnrin Netaniah, Johanani àti Jonatani ọmọkùnrin ti Karea, Seraiah ọmọkùnrin Tanhumeti tí í ṣe ọmọkùnrin Efai ará Netofa àti Jesaniah ọmọkùnrin Maakati àti àwọn ènìyàn wọn.
9 Gedalaia da ilima amane sia: i, “Na dilima dafawane sia: sa. Mae beda: ma! Ba: bilone dunu dili gagulaligisa: besa: le, amoga mae masa. Be guiguda: amo moi dogole noga: le fili, Ba: bilone hina bagade ea hawa: hamosa esaloma. Amasea, dilia da hahawane esalumu.
Gedaliah ọmọkùnrin Ahikamu, ọmọkùnrin ti Ṣafani ṣe ìbúra láti tún fi dá àwọn ènìyàn lójú pé, “Ẹ má ṣe bẹ̀rù láti sin àwọn Babeli.” Ó sọ wí pé, “Gbé ilẹ̀ náà kí ẹ sì máa sin ọba Babeli, yóò sì dára fún un yín.
10 Na nisu da Misiba guiguda: esalumu. Amola Ba: bilone dunu da guiguda: masea, na da dilia alofele iasu dunu agoane ba: mu. Be dilia ha: i manu bugili, waini hano, ifa fage amola olife susuligi noga: le lama. Amola hahawane dilia diasudafa amo ganodini esaloma.”
Èmi fúnra mi yóò dúró ní Mispa láti ṣojú yín níwájú Babeli tí wọ́n tọ̀ wá wá. Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ni yóò máa kórè ọtí wáìnì, èso igi àti òróró; kí ẹ sì kó wọn sí inú àpò àpamọ́wọ́ yín; kí ẹ̀yin sì máa gbé ní ìlú tí ẹ ti gbà.”
11 Isala: ili fi dunu amo da Moua: be soge amola A: mone soge amola Idome soge amo ganodini esaloba, da Ba: bilone hina bagade da Isala: ili dunu mogili Yuda soge ganodini esaloma: ne amola Gedalaia ouligima: ne, logo doasi dagoi amo nabi.
Nígbà tí gbogbo àwọn Juda ní Moabu, Ammoni, Edomu àti gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè gbọ́ pé ọba Babeli ti fi ohun tókù sílẹ̀ ní Juda, àti pé ó ti yan Gedaliah ọmọkùnrin Ahikamu ọmọkùnrin Ṣafani gẹ́gẹ́ bí gómìnà lórí wọn.
12 Amaiba: le, ilia da soge amoga ilia da afagogoi ba: i, amo yolesili, Yuda sogega buhagi. Ilia da Gedalaia, Misiba moilaiga esalu, ema buhagi. Amogawi, ilia da waini amola ifa fage bagohame faili gagadoi.
Gbogbo wọn padà wá sí ilẹ̀ Juda sọ́dọ̀ Gedaliah ní Mispa láti orílẹ̀-èdè gbogbo tí a ti lé wọn sí. Wọ́n sì kórè ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọtí wáìnì àti èso igi.
13 Amo fa: no, Youha: ina: ne amola dadi gagui amo da Ba: bilonega hame asi, ilia ouligisu dunu da Gedalaia, Misiba moilaiga esalu, ema misi.
Johanani ọmọkùnrin ti Karea àti gbogbo àwọn olórí ogun tí ó kù ní orílẹ̀-èdè sì tọ Gedaliah wá ní Mispa.
14 Ilia da ema amane sia: i, “A: mone hina bagade Ba: ialaise da Isama: iele di medole legemusa: asunasi dagoi.” Be Gedalaia da ilia sia: dafawaneyale hame dawa: i.
Wọ́n sì sọ fún un wí pé, “Ǹjẹ́ ìwọ ha mọ̀ pé Baalisi ọba àwọn Ammoni ti rán Iṣmaeli ọmọkùnrin Netaniah láti lọ mú ẹ̀mí rẹ?” Ṣùgbọ́n Gedaliah ọmọkùnrin ti Ahikamu kò gbà wọ́n gbọ́.
15 Amalalu, Youha: ina: ne da ema wamowane sia: i, “Na da Isama: iele ema asili medole legemusa: , dia na logo doasima. Dunu huluane e fasu dunu hame dawa: mu. E da di medole legemu da defea hame. Amai hamoi ganiaba, Yu dunu amo dima gilisi da bu afagogoi dagoi ba: mu. Amola se nabasu amola wadela: su da dunu huluane Yuda soge ganodini esalebe ilima doaga: mu.”
Nígbà náà ni Johanani ọmọkùnrin Karea sọ ní ìkọ̀kọ̀ fún Gedaliah ní Mispa pé, “Jẹ́ kí èmi lọ pa Iṣmaeli ọmọkùnrin Netaniah, ẹnikẹ́ni kò sì ní mọ èyí. Kí ni ìdí rẹ̀ tí yóò ṣe mú ẹ̀mí rẹ, tí o sì ṣe fẹ́ mú àwọn Júù tí ó yí ọ ká túká, kí ìyókù Juda sì parun?”
16 Be Gedalaia da bu adole i, “Amo hou mae hamoma! Dia Isama: iele ea hou nama olelebe da ogogosa.”
Ṣùgbọ́n Gedaliah ọmọ Ahikamu sọ fún Johanani ọmọ Karea pé, “Má ṣe ṣe nǹkan yìí! Nítorí nǹkan tí ò ń sọ nípa Iṣmaeli kì í ṣe òtítọ́.”

< Yelemaia 40 >