< Yelemaia 39 >

1 Oubi nabuane gala, Yuda hina bagade Sedegaia ea ouligisu ode sesegeyale amoga, Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese amola ea dadi gagui wa: i huluane da misini, Yelusaleme amoma doagala: i.
Ó sì ṣe, nígbà tí a kó Jerusalẹmu, ní ọdún kẹsànán Sedekiah, ọba Juda, nínú oṣù kẹwàá, Nebukadnessari ọba Babeli gbógun ti Jerusalẹmu pẹ̀lú gbogbo ogun rẹ̀, wọ́n sì dó tì í.
2 Eso sesegeyale, oubi biyadu amola hina bagade Sedegaia ea ouligibi ode gidayale amoga, Ba: bilone dunu ilia da Yelusaleme ea gagoi dobea amo fili mugului.
Ní ọjọ́ kẹsànán, oṣù kẹrin ọdún kọkànlá Sedekiah, ni a wó odi ìlú náà.
3 (Ilia da Yelusaleme amoma hasalasili, Ba: bilone hina bagade ea eagene ouligisu dunu bagade da sogebi Dogoa Logo Ga: su amoga misini lelu. Mogili ilia dio da Naiga: le Sialisa, Sa: maga Nibou, Sasigimi amola Naiga: le Sialisa eno.)
Nígbà náà ni gbogbo àwọn ìjòyè ọba Babeli wá, wọ́n sì jókòó ní àárín ẹnu ibodè, àní Nergali-Ṣareseri ti Samgari, Nebo-Sarsikimu olórí ìwẹ̀fà, Nergali-Ṣareseri, olórí amòye, pẹ̀lú gbogbo àwọn ìjòyè ọba Babeli yóò kú.
4 Hina bagade Sedegaia amola ea dadi gagui dunu huluane da ilima doaga: mu hou ba: beba: le, ilia da gasia moilai bai bagadega hobeale masunu dawa: i. Ilia da hina bagade ea ifabi amoga asili, amola logo holei amo da dobea aduna ea disisu diala, amoga asili, Yodane Fago amoga doaga: musa: hobea: i.
Nígbà tí Sedekiah ọba Juda àti àwọn ọmọ-ogun rí wọn, wọ́n sá, wọ́n kúrò ní ìlú ní alẹ́, wọ́n gba ọ̀nà ọgbà ọba lọ láàrín ẹnu ibodè pẹ̀lú odi méjì, wọ́n dojúkọ aginjù.
5 Be Ba: bilone dadi gagui wa: i da ilima fa: no bobogele, ilia da umi soge Yeligou moilai bai bagade gadenene amoga Sedegaia gagulaligili, hina bagade Nebiuga: denesema afugili asi. Nebiuga: denese da Libala moilai bai bagade Ha: ima: de soge amo ganodini esalebe ba: i. Amogawi, e da Sedegaia ema fofada: nanu, ema se ima: ne sia: i.
Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn ọmọ-ogun Babeli lé wọn, wọ́n bá Sedekiah láàrín aginjù Jeriko. Wọ́n mú un ní ìgbèkùn, wọ́n sì mú u tọ Nebukadnessari ọba Babeli àti Ribla ní ilẹ̀ Hamati, níbi tí wọ́n ti ṣe ìdájọ́ rẹ̀.
6 E da Libala moilai bai bagadega Sedegaia ba: ma: ne, egefe huluane medole lelegei. Amola e da Yuda eagene ouligisu dunu huluane medole lelegei.
Níbẹ̀ ní Ribla, ni ọba Babeli ti dúńbú àwọn ọmọ Sedekiah lójú rẹ̀, tí ó sì tún pa gbogbo àwọn ọlọ́lá ilẹ̀ Juda.
7 Amalalu, ea sia: beba: le, ilia da Sedegaia ea si aduna duga: le fasili, e sia: inega la: gili, Ba: bilone sogega afugili asi.
Nígbà náà ni ó fọ́ ojú Sedekiah, ó sì dè é pẹ̀lú ẹ̀wọ̀n láti gbé e lọ sí ilẹ̀ Babeli.
8 Amola Ba: bilone dunu da Yelusaleme hina bagade diasu amola dunu ilia diasu huluane laluga ulagi. Ilia da Yelusaleme gagoi dobea huluane mugululi, wadela: lesi dagoi.
Àwọn Babeli dáná sun ààfin ọba àti ilé àwọn ènìyàn, wọ́n sì wó odi Jerusalẹmu.
9 Amalalu, dadi gagui wa: i ouligisu bagade Nebiusala: ida: ne, e da dunu huluane Yelusaleme ganodini esalu amola Yuda dunu huluane amo da hohonone, Yuda hina bagade yolesili ema hobea: i, e da amo huluane gagulaligili, Ba: bilone sogega udigili hawa: hamoma: ne oule asi.
Nebusaradani olórí àwọn ọmọ-ogun mú lọ sí ìgbèkùn Babeli pẹ̀lú gbogbo àwọn tí ó ṣẹ́kù nínú ìlú.
10 Be e da liligi hamedafa gagui dunu amo Yuda soge ganodini bu esaloma: ne, logo doasi. Amola e da amo dunuma waini sagai amola soge i.
Ṣùgbọ́n Nebusaradani olórí ogun fi àwọn aláìní sílẹ̀ ní Juda, àwọn tí kò ní ohun kankan ní àkókò náà, ó fún wọn ní ọgbà àjàrà àti oko.
11 Be hina bagade Nebiuga: denese da dadi gagui wa: i ouligisudafa Nebiusala: ida: ne ema amane sia: i,
Nísinsin yìí, Nebukadnessari ọba àwọn Babeli pàṣẹ lórí Jeremiah, láti ọ̀dọ̀ Nebusaradani olórí ogun wá wí pé:
12 “Yelemaia amo hogola masa. Amola e noga: le ouligima. Ema se mae ima, be ea hanai amo hamoma.”
“Ẹ gbé e, kí ẹ sì bojútó o. Ẹ má ṣe ṣe ohun búburú fún un, ṣùgbọ́n ohunkóhun tó bá béèrè ni kí ẹ fi fún un.”
13 Amaiba: le, Nebiusala: ida: ne amola eno ouligisu bagade dunu amo Nebiusia: saba: ne amola Naiga: le Sialisa, amola Ba: bilone hina bagade ea eagene ouligisu dunu huluane,
Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ pẹ̀lú, Nebusaradani balógun ìṣọ́, àti Nebusaradani olórí ìwẹ̀fà, àti Nergali-Ṣareseri, olórí amòye àti gbogbo àwọn ìjòyè ọba Babeli,
14 ilia da hina bagade diasu gagoi amoga na lale, Gedalaia (Ahaiga: me egefe amola Sia: ifa: ne ea aowa) amo na ouligima: ne, ema oule asi. Gedalaia da na ouligili, na da na diasuga hahawane doaga: ma: ne, ouligimu ilia sia: i. Amaiba: le, na da dunu fi ilia esalebe ganodini esalu.
ránṣẹ́ láti mú Jeremiah kúrò nínú túbú. Wọ́n gbé e lọ fún Gedaliah ọmọ Ahikamu ọmọ Ṣafani láti mú padà lọ sí ilé àti máa wà pẹ̀lú àwọn ènìyàn rẹ̀.
15 Na da musa: hina bagade diasu gagoi gagili ga: i diasu agoane amo ganodini esaloba, Hina Gode da nama amane sia: i,
Nígbà tí Jeremiah wà nínú túbú, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ ọ́ wá wí pé:
16 “Dia Ibedemilege (Suda: ne dunu) ema ‘Na, Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili fi ilia Gode, da amane sia: sa, ‘Na sia: i defele, Na da amo moilai bai bagadega hahawane bagade gagui hou hame imunu. Be Yelusaleme da wadela: lesi dagoi ba: mu. Amola amo hou da doaga: sea, di, Ibedemilege da amo ba: mu.
“Lọ sọ fún Ebedimeleki ará Kuṣi, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí: Èmi ṣetán láti mú ọ̀rọ̀ mi ṣẹ lórí ìlú yìí nípa àjálù kì í ṣe àlàáfíà. Ní àkókò náà ni yóò ṣẹ lójú rẹ.
17 Be Na, Hina Gode, Na da di gaga: mu amola dunu (ilima dia da beda: i) ilia da di hame gagulaligimu.
Ṣùgbọ́n, Èmi yóò gbà ọ́ lọ́jọ́ náà ni Olúwa wí. A kò ní fi ọ́ lé ọwọ́ àwọn tí o bẹ̀rù.
18 Na da di gaga: mu amola di da hame medole legei dagoi ba: mu. Di da esalumu. Bai di da Na hou dafawaneyale dawa: beba: le, lalegagui dagoi. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.’”
Èmi yóò gbà ọ́ là; o kò ní ṣubú láti ipa idà; ṣùgbọ́n ìwọ yóò sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ, nítorí pé ìwọ ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú mi, ni Olúwa wí.’”

< Yelemaia 39 >