< Yelemaia 28 >

1 Amo odega, oubi bi amoga amola Sedegaia ea ouligibi ode biyale amoga, balofede dunu ea dio amo Ha: nanaia (e da A: sie egefe amola ea moilai da Gibione) da Debolo diasu ganodini nama sia: i. Gobele salasu dunu huluane amola dunu eno huluane ba: ma: ne, e da nama amane sia: i,
Ní oṣù karùn-ún ní ọdún kan náà, ọdún kẹrin ní ìbẹ̀rẹ̀ ìṣèjọba Sedekiah ọba Juda, wòlíì Hananiah ọmọ Assuri, tí ó wá láti Gibeoni, sọ fún mi ní ilé Olúwa tí ó wà ní iwájú àwọn àlùfáà àti gbogbo ènìyàn:
2 “Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili fi ilia Gode, da nama amane sia: i, ‘Na da Ba: bilone hina bagade amo ea gasa fi dagoi.
“Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Èmi yóò mú àjàgà ọba Babeli rọrùn.
3 Ode aduna da mae gidigili, Na da Debolo liligi ida: iwane gala amo hina bagade Nebiuga: denese da Ba: bilone sogega gaguli asi, amo huluane bu Yelusalemega gaguli misunu.
Láàrín ọdún méjì, Èmi yóò mú gbogbo ohun èlò tí ọba Nebukadnessari; ọba Babeli kó kúrò ní ilé Olúwa tí ó sì kó lọ sí Babeli padà wá.
4 Amola Na da Yuda hina bagade, Yehoiagini (Yihoiagimi egefe) amola Yuda fi dunu huluane Ba: bilone sogega mugululi asi, amo huluane Yuda sogega buhagima: ne oule misunu. Dafawane! Na da Ba: bilone hina bagade ea gasa wadela: lesimu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi,’” Ha: nanaia da amane sia: i.
Èmi á tún mú ààyè Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda padà, àti gbogbo àwọn tí ń ṣe àtìpó láti Juda ní Babeli,’ èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa pé, ‘àjàgà yín láti ọwọ́ ọba Babeli yóò rọrùn.’”
5 Amalalu, gobele salasu dunu amola dunu huluane Debolo Debolo ganodini lelu, amo nabima: ne, na da Ha: nanaiama amane sia: i,
Wòlíì Jeremiah wí fún wòlíì Hananiah ní iwájú ọmọ àlùfáà àti àwọn ènìyàn tí wọ́n dúró ní ilé Olúwa.
6 “Defeadafa! Hina Gode da agoane hamosea, na da hahawane bagade ba: mu. Dia ba: la: lusu da dafawane ba: sea, amola Hina Gode da Debolo liligi Ba: bilone amoga gaguli asi amola Yuda fi dunu mugululi asi, amo huluane bu oule masea, na da hahawane ba: mu.
Jeremiah wòlíì wí pé, “Àmín! Kí Olúwa kí ó ṣe bẹ́ẹ̀! Kí Olúwa kí ó mú ọ̀rọ̀ rẹ̀ tí ìwọ sọ àsọtẹ́lẹ̀ ṣẹ, láti mú ohun èlò ilé Olúwa àti gbogbo àwọn ìgbèkùn láti ilẹ̀ Babeli padà wá sí ibí yìí.
7 Be na da dima amola dunu huluane ilima, sia: galaiou. Nabima!
Nísinsin yìí, ìwọ gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí tí mo sọ sí etí rẹ àti sí etí gbogbo ènìyàn.
8 Musa: hemonega, di amola na amola ani hame lalelegeiya, balofede dunu ilia da amane ba: la: lusu; gegesu amola ha: amola olo bagade da gasa bagade fifi asi gala amola hina bagade ilia fi ilima doaga: mu.
Ní ìbẹ̀rẹ̀ àwọn wòlíì tí ó ṣáájú rẹ àti èmi ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ ogun, ibi àti àjàkálẹ̀ sí ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè.
9 Be balofede dunu da olofosu fawane ba: la: lusu, amo ea hou ninia da agoane adoba: sa. Ea ba: la: lusu sia: i da dafawane doaga: i dagoi ba: sea fawane, Hina Gode da amo balofede asunasi, ninia dawa:”
Ṣùgbọ́n, àwọn wòlíì tí ó ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ àlàáfíà ni a mọ̀ gẹ́gẹ́ bí wòlíì olóòtítọ́ tí Olúwa rán, tí àsọtẹ́lẹ̀ rẹ bá wá sí ìmúṣẹ.”
10 Amalalu, Ha: nanaia da “youge” na galogoa amoga fadegale, fifi dagoi.
Wòlíì Hananiah gbé àjàgà ọrùn wòlíì Jeremiah kúrò, ó sì fọ́ ọ.
11 E da dunu huluane nabima: ne amane sia: i, “Hina Gode da ‘youge’ amo hina bagade Nebiuga: denese da fifi asi gala ilia galogoaga gasisali, amo fifimu. Ode aduna da hame gidigili, E da agoane hamomu.” Amalalu, na da fisili asi.
Hananiah sọ níwájú gbogbo ènìyàn wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Bákan náà ni Èmi yóò fọ́ àjàgà ọrùn Nebukadnessari, ọba Babeli láàrín ọdún méjì.’” Wòlíì Jeremiah sì bá ọ̀nà tirẹ̀ lọ.
12 Ouesalu, Hina Gode da na da Ha: nanaiama masa: ne sia: i.
Láìpẹ́ ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wòlíì wá lẹ́yìn ìgbà tí wòlíì Hananiah ti gbé àjàgà kúrò ní ọrùn wòlíì Jeremiah wí pé:
13 E da na Ha: nanaiama amane sia: ma: ne sia: i, “Hina Gode da amane sia: sa ‘Di da ifaga hamoi ‘youge’ fimusa: dawa: Be Na da amo ea sogebiga, ouli ‘youge’ legemu.’
“Lọ sọ fún Hananiah, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí, ìwọ ti wó àjàgà onígi, ṣùgbọ́n ní ààyè wọn, wà á bá àjàgà onírin.
14 Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili dunu ilia Gode, da amo fifi asi gala huluane ilia Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese ea udigili hawa: hamomusa: gini, ilia galogoaga ouli ‘youge’ gasisalimu. Hina Gode hamobeba: le, dunu huluane amola sigua ohe da Nebiuga: denese ea udigili hawa: hamomu, Hina Gode da amane sia: i dagoi.”
Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí: Èmi yóò fi àjàgà onírin sí ọrùn gbogbo orílẹ̀-èdè láti lè máa sin Nebukadnessari ọba Babeli, àti pé gbogbo yín ni ẹ̀ ó máa sìn ín. Èmi yóò tún fún un ní àṣẹ lórí àwọn ẹranko búburú.’”
15 Amo sia: huluane na da Ha: nanaiama sia: i, amola eno amane sia: i, “Ha: nanaia! Di nabima! Hina Gode da di hame asunasi. Amola, dunu da giadofale dawa: ma: ne, di da ilima ogogosa.
Wòlíì Jeremiah sọ fún wòlíì Hananiah pé, “Gbọ́ ọ, Hananiah! Olúwa kò rán ọ, síbẹ̀, ìwọ jẹ́ kí orílẹ̀-èdè yìí gba irọ́ gbọ́.
16 Amaiba: le, Hina Gode Hisu da di fadegamusa: sia: sa. Wali ode da mae gidigili, di da bogomu. Bai di da dunu ilia Hina Godema odoga: ma: ne olelei.”
Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Mo ṣetán láti mú ọ kúrò nínú ayé, ní ọdún yìí ni ìwọ yóò kú nítorí o ti wàásù ọ̀tẹ̀ sí Olúwa.’”
17 Amola Ha: nanaia da oubi fesu amo odega fawane, bogoi dagoi.
Ní oṣù keje ọdún yìí ni Hananiah wòlíì kú.

< Yelemaia 28 >