< Yelemaia 32 >

1 Yuda hina bagade Sedegaia ea ouligibi ode nabuane amoga (amo ode da Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese ea ouligibi ode 18), Hina Gode da nama sia: i.
Èyí ni ọ̀rọ̀ tó tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa ní ọdún kẹwàá Sedekiah ọba Juda, èyí tí ó jẹ́ ọdún kejìdínlógún ti Nebukadnessari.
2 Amo ode ganodini, Nebiuga: denese da Yelusalemema doagala: lebe ba: i. Na da hina bagade diasu gagoi amo ganodini udigili hawa: hamosu dunu agoane esalebe ba: i.
Àwọn ogun ọba Babeli ìgbà náà há Jerusalẹmu mọ́. A sì sé wòlíì Jeremiah mọ́ inú túbú tí wọ́n ń ṣọ́ ní àgbàlá ilé ọba Juda.
3 Yuda hina bagade Sedegaia da na amoga udigili hawa: hamoma: ne sia: i. Bai e da nama diwane udidili, na da Hina Gode Ea sia: i liligi ogogole olelei, e sia: i. Be Hina Gode da dafawane amane sia: i dagoi, “Na da Ba: bilone hina bagade amo moilai bai bagade doagala: le fefedema: ne, logo doasimu.
Nítorí Sedekiah ọba Juda ti há a mọ́lé síbẹ̀; pé, “Kí ló dé tí ìwọ fi ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ bẹ́ẹ̀? Tí o sì wí pé, ‘Báyìí ni Olúwa wí: Èmi ń bọ̀ wá fi ìlú yìí fún ọba Babeli, tí yóò sì gbà á.
4 Amola hina bagade Sedegaia da hobeale masunu hamedei ba: mu. Ba: bilone hina bagade da e gagulaligimu. E da e odagi ba: mu amola ea odagia sia: mu.
Sedekiah ọba Juda kò lè bọ́ lọ́wọ́ àwọn Kaldea, ṣùgbọ́n à ó mú fún ọba Babeli, yóò sì bá sọ̀rọ̀ ní ojúkojú; yóò sì rí pẹ̀lú ojú rẹ̀.
5 Ba: bilone hina bagade da e afugili, Ba: bilone sogega hiouginana masunu. E da amogawi esalu, Na da ema dabe imunu. E da Ba: bilone fi ilima dabe gegesea, e da osa: la heda: mu hame dawa: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Yóò mú Sedekiah lọ sí Babeli tí yóò wà títí èmi yóò fi bẹ̀ ọ́ wò ni Olúwa wí. Tí ẹ̀yin bá bá àwọn ará Kaldea jà, ẹ̀yin kì yóò borí wọn.’”
6 Hina Gode da nama amane sia: i,
Jeremiah wí pé, “Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
7 “Ha: namele, (dia aowa Sia: lame egefe) da dima misini, e da di ea soge A: nanode moilai bai bagade gadenene, Bediamini soge amo ganodini, amo dima bidi lama: ne sia: mu. Bai di da ea gadenene sosogo fidafa amola eno hame be di fawane bidi lamu da sema defele gala.”
Hanameli ọmọkùnrin Ṣallumu ẹ̀gbọ́n rẹ̀ yóò tọ̀ ọ́ wá pé, ‘Ra pápá mi tí ó wà ní Anatoti; nítorí gẹ́gẹ́ bí ẹni tó súnmọ́ wọn, ẹ̀tọ́ àti ìṣe rẹ ní láti rà á.’
8 Amalalu, Hina Gode Ea sia: i defele, Ha: namele da Debolo gagoi amoga nama misini, na da ea soge bidi lama: ne sia: i. Amaiba: le, Hina Gode da nama dafawane sia: i dagoi, na da dawa: i galu.
“Gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti sọ, Hanameli ọmọ ẹ̀gbọ́n mi tọ̀ mí wá ní àgbàlá túbú wí pé, ‘Ra pápá mi tí ó wà ní Anatoti tí ó wà ní ilẹ̀ Benjamini, èyí tí ó jẹ́ pé ẹ̀tọ́ rẹ ni láti gbà á àti láti ni, rà á fún ara rẹ.’ “Nígbà náà ni èmi mọ̀ wí pé ọ̀rọ̀ Olúwa ni èyí.
9 Na da Ha: namele amoga ea soge bidi lai. Na da muni ea dioi defei ba: lalu, amo ema i. Silifa ea idi da17 agoane ba: i.
Bẹ́ẹ̀ ni; èmi ra pápá náà ní Anatoti láti ọwọ́ Hanameli ọmọ ẹ̀gbọ́n mi. Mo sì wọn ìwọ̀n ṣékélì àti fàdákà mẹ́tàdínlógún fún un.
10 Na da soge bidi lamu meloa amoga na dio dedei amola amoga gobele legesu liligiga legei. Ba: su dunu da amo hou ba: i dagoi amola muni da dioi ba: su amoga ea dioi defei ba: i.
Mo fọwọ́ sínú ìwé, mo sì dì í pa. Mo pe ẹlẹ́rìí sí i, mo sì wọn fàdákà náà lórí òsùwọ̀n.
11 Amalalu, na da soge bidi lasu meloa amoga ba: le dedei aduna (afae da gobele legesuga ga: i, eno da hame ga: i) amo lale,
Mo mú ìwé tí mo fi rà á, èyí tí a di pa nípa àṣẹ àti òfin wa, àti èyí tí a kò lẹ̀.
12 Belage (Nilaia egefe amola Masaia ea aowa) ema i. Na da Ha: namele amola ba: su dunu (amo da soge bidi lasu meloa amoga ilia dio dedei) amola dunu da gagoi ganodini fi dialu, amo huluane ba: ma: ne, na da Belagema i.
Èmi sì fi èyí fún Baruku, ọmọ Neriah, ọmọ Maseiah, ní ojú Hanameli, ọmọ ẹ̀gbọ́n mi àti níwájú àwọn ẹlẹ́rìí tí ó ti fi ọwọ́ sí ìwé àti ní ojú àwọn Júù gbogbo tí wọ́n jókòó ní àgbàlá ilé túbú.
13 Na da ilia midadi lelu, Belagema amane sia: i,
“Ní ojú wọn ni èmi ti pàṣẹ fún Baruku pé,
14 “Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili fi ilia Gode, da dilia amo soge bidi lasu meloa (meloa amo da gobele legesuga ga: i amola meloa eno hame ga: i) amo lale, ode bagohame dialoma: ne, laga osoboga hamoi ofodo amo ganodini salima: ne sia: sa.
èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí; mú àwọn ìwé tí a fi rà á wọ̀nyí, àti èyí tí a lẹ̀ àti èyí tí a kò lẹ̀, kí o wá gbé wọn sínú ìkòkò amọ̀, kí wọn ó lè wà ní ọjọ́ púpọ̀.
15 Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili fi ilia Gode, da fa: no agoane, Isala: ili soge ganodini, dunu ilia da diasu amola soge amola waini efe sagai amo bidi lalebe ba: mu, amane sia: sa.”
Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí; àwọn ilẹ̀, pápá àti ọgbà àjàrà ni à ó tún rà padà nílẹ̀ yìí.
16 Na da soge bidi lasu meloa amo Belagema ia dagolalu, na da Godema sia: ne gadoi, amane,
“Lẹ́yìn tí mo ti fi ìwé rírà náà fún Baruku ọmọkùnrin Neriah, mo gbàdúrà sí Olúwa wí pé:
17 “Ouligisudafa Hina Gode! Di da osobo bagade amola mu amo Dia gasa bagade amoga hamoi. Dia hamomu hamedei liligi da hame gala.
“Háà! Olúwa Olódùmarè, ìwọ tí o dá ọ̀run àti ayé pẹ̀lú títóbi agbára rẹ àti gbogbo ọ̀rọ̀ apá rẹ. Kò sí ohun tí ó ṣòro fún ọ láti ṣe.
18 Di da dunu osea: i ilima Dia dogolegei hou olelelala. Be dunu eno ilima ilia ada amola ame da wadela: le hou hamobeba: le, Di da se iaha. Di da bagade amola gasa bagade gala. Di da Hina Gode Bagadedafa.
O fi ìfẹ́ hàn sí ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn ènìyàn, ṣùgbọ́n o gbé ìyà ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba lé àwọn ọmọ lẹ́yìn wọn. Ọlọ́run títóbi àti alágbára, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ.
19 Di da noga: i bagade dawa: su ilegesu hamosa, amola gasa bagade hamonana. Osobo bagade fi dunu huluane ilia hamobe Dia da ba: lala. Amola, ilia hamoi defele, ilima dabe iaha.
Títóbi ni ìgbìmọ̀, àti alágbára ní í ṣe, ojú rẹ̀ ṣì sí gbogbo ọ̀nà àwọn ọmọ ènìyàn; láti fi fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ ọ̀nà rẹ̀ àti gẹ́gẹ́ bí èso iṣẹ́ rẹ̀.
20 Hemonega, Di da Idibidi sogega musa: hame ba: su gasa bagade dawa: digima: ne olelesu hou hamosu. Amola Di da wali amola, Isala: ili soge ganodini amola fifi asi gala huluane, ilia soge ganodini, amo gasa bagade hou hamonana. Amaiba: le, soge huluane amo ganodini, dunu da Dia hou dawa: digisa.
O ṣe iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu ńlá ní Ejibiti. O sì ń ṣe é títí di òní ní Israẹli àti lára ọmọ ènìyàn tí ó sì ti gba òkìkí tí ó jẹ́ tìrẹ.
21 Dia da musa: hame ba: su gasa bagade hou hamobeba: le, ninia ha lai da bagade beda: i. Amola amo gasa bagade hou amoga Di da Dia fi Isala: ili dunu, amo Idibidi sogega fisili masa: ne, ga asunasi.
O kó àwọn Israẹli ènìyàn rẹ jáde láti Ejibiti pẹ̀lú iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu nínú ọwọ́ agbára àti nína apá rẹ pẹ̀lú ẹ̀rù ńlá.
22 Di da ilia aowalali ilima ilegele sia: i defele, amo noga: i amola nasegagi soge ilima i.
Ìwọ fún wọn nílẹ̀ yìí, èyí tí o ti ṣèlérí fún àwọn baba ńlá wọn; ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin.
23 Be ilia da amo sogega misini, lalegaguli, ilia da Dia hamoma: ne sia: i hame nabi amola Dia olelesu amo defele hame esalusu. Ilia da Dia hamoma: ne sia: i huluanedafa yolesi dagoi. Amaiba: le, Di da ilima se ima: ne amo gugunufinisisu ilima i.
Wọ́n wá, wọ́n sì gba ilẹ̀ náà ṣùgbọ́n wọn kò gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ tàbí tẹ̀lé òfin rẹ. Wọn kò ṣe ohun tí o pàṣẹ fún wọn, nítorí náà ìwọ mú àwọn ibi yìí wá sórí wọn.
24 Ba: bilone dadi gagui da Yelusaleme amoma doagala: sa amola amo sisiga: le, ilia da gegesu bi amo hamoi dagoi. Gegesu amola ha: bagade amola olosu da ilima doaga: beba: le, Yelusaleme da dafamu amola Ba: bilone dunu da hasalimu. Hina Gode! Di ba: ma! Dia sia: i liligi huluane da dafawane doaga: i dagoi.
“Wò ó, bí àwọn ìdọ̀tí ṣe kórajọ láti gba ìlú. Nítorí idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn, sì fi ìlú lé ọwọ́ àwọn ará Kaldea tí ń gbóguntì wọ́n. Ohun tí ìwọ sọ ṣẹ gẹ́gẹ́ bí o ṣe rí i.
25 Be Ouligisudafa Hina Gode! Disu da amo soge, ba: su dunu ba: ma: ne bidi lama: ne, nama sia: i. Ba: bilone dunu da hasalili, Yelusaleme wahadafa lamu gala, be Di da amo soge bidi lama: ne nama sia: i.”
Síbẹ̀ a ó fi ìlú náà fún àwọn ará Babeli, ìwọ Olúwa Olódùmarè sọ fún mi pé, ‘Ra pápá náà pẹ̀lú owó fàdákà, kí o sì pe ẹlẹ́rìí.’”
26 Amalalu, Hina Gode da nama amane sia: i,
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá pé:
27 “Na da osobo bagade dunu fi ilima Hina Gode esala. Liligi Na hamomu hamedei da Nama hame gala.
“Èmi ni Olúwa Ọlọ́run gbogbo ẹran-ara. Ǹjẹ́ ohun kan ha a ṣòro fún mi bí?
28 Na da amo moilai bai bagade Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese amola ea dadi gagui wa: i dunu ilima imunu. Ilia da amo lale,
Nítorí náà, báyìí ni Olúwa wí, Èmi ṣetán láti fi ìlú yìí fún àwọn ará Kaldea àti fún Nebukadnessari ọba Babeli ẹni tí yóò kó o.
29 laluga ulagimu. Ilia da amo moilai bai bagade, amola ea diasu huluane (amo ganodini, dunu da Na ougima: ne, diasu gadodili Ba: ielema nodomusa: gabusiga: manoma ulagisu amola eno ogogosu ‘gode’ ilima nodomusa: , waini hano sogadigi) amo huluane ilia nene dagoma: ne ulagimu.
Àwọn ará Kaldea tí ó ń gbógun tí ìlú yóò wọ ìlú. Wọn ó sì fi iná sí ìlú; wọn ó jó o palẹ̀ pẹ̀lú ilé tí àwọn ènìyàn ti ń mú mi bínú, tí wọ́n ń rú ẹbọ tùràrí lórí pẹpẹ fún Baali tiwọn sì ń da ẹbọ ohun mímu fún àwọn ọlọ́run mìíràn.
30 Isala: ili fi da degabo fi hamoi amogainini wali amola, Isala: ili fi amola Yuda fi ilia da Na ougima: ne, hame nabasu hou hamosu.
“Àwọn ènìyàn Israẹli àti Juda kò ṣe ohun kankan bí kò ṣe ibi lójú mi láti ìgbà èwe wọn. Nítorí àwọn ọmọ Israẹli ti fi kìkì iṣẹ́ ọwọ́ wọ́n mú mi bínú ni Olúwa wí.
31 Amola Yelusaleme fi da amo moilai bai bagade degabo gaguli, amogainini wali amola da Na ougima: ne wadela: le hamosu. Amaiba: le, Na da amo moilai bai bagade wadela: musa: ilegei dagoi.
Láti ọjọ́ tí wọ́n ti kọ́ ọ, títí di àkókò yìí ni ìlú yìí ti jẹ́ ohun ìbínú àti ìyọnu fún mi tó bẹ́ẹ̀ tí èmi yóò fà á tu kúrò níwájú mi.
32 Bai Yuda dunu, Yelusaleme dunu, ilia hina bagade, ouligisu dunu, ilia gobele salasu amola ilia balofede dunu huluane da wadela: le hamoi dagoi.
Àwọn ènìyàn Israẹli àti àwọn ènìyàn Juda ti mú mi bínú pẹ̀lú gbogbo ìbàjẹ́ tí wọ́n ṣe. Àwọn Israẹli, ọba wọn àti gbogbo ìjòyè, àlùfáà àti wòlíì, àwọn ọkùnrin Juda àti àwọn ènìyàn Jerusalẹmu.
33 Ilia da Nama baligi fa: su. Na da ilima gebewane olelelalusu, be ilia da hamedafa nabasu, amola dawa: digimu hame dawa: i.
Wọ́n kọ ẹ̀yìn sí mi, wọ́n sì yí ojú wọn padà. Èmi kọ wọ́n, síbẹ̀ wọn kò fetísílẹ̀ láti gbọ́ ẹ̀kọ́ tàbí kọbi ara sí ìwà ìbàjẹ́.
34 Ilia da hame nabasu hou baligili, Debolo diasu (amo da Nama nodone sia: ne gadomusa: gagui) amo ganodini ilia wadela: idafa loboga hamoi ogogosu ‘gode’ ligisiba: le, Na Debolo diasu da ledo agoane hamoi ba: sa.
Wọ́n kó òrìṣà ìríra wọn jọ sí inú ilé tí wọ́n fi orúkọ mi pè, wọ́n sì ṣọ́ di àìmọ́.
35 Ilia da Hinome Fago amoga Ba: ielema oloda hamosu. Amogai ilia da ogogosu ‘gode’ Moulege ema ilia egefe amola idiwi medole lelegele, gobele salasu hou hamosa. Na da amo hou ilia hamoma: ne da hamedafa sia: i. Ilia da amo hou hamomu amola Yuda dunu wadela: le hamoma: ne hamobe, amo Na asigi dawa: suga hamedafa dawa: iou.”
Wọ́n kọ́ ibi gíga fún Baali ní àfonífojì Hinnomu láti fi ọmọ wọn ọkùnrin àti obìnrin rú ẹbọ sí Moleki. Èmi kò pàṣẹ, fún wọn, bẹ́ẹ̀ ni kò wá sí ọkàn mi pé kí wọ́n ṣe ohun ìríra wọ̀nyí tí ó sì mú Juda dẹ́ṣẹ̀.
36 Hina Gode, Isala: ili fi ilia Gode, da nama amane sia: i, “Yelemaia! Dunu da amo gegesu amola ha: bagade amola olosu da ilima doaga: beba: le, Yelusaleme da dafane, Ba: bilone hina bagade ea lobo da: iya gagui dialebe ba: mu. Be nabima! Na da sia: eno galaiou!
“Ìwọ ń sọ̀rọ̀ nípa ti ìlú yìí pé, ‘Pẹ̀lú idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn ni à ó fi wọ́n fún ọba Babeli,’ ṣùgbọ́n ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ nìyìí,
37 Na da bagade ougiba: le, amo fi dunu fifi asi gala eno huluane amo ganodini esaloma: ne afagogole sefasimu. Be fa: no, Na da amo dunu huluane bu gagadole, guiguda: bu oule misunu. Amasea, ilia da guiguda: olofole, gaga: iwane esalumu.
Èmi ó kó wọn jọ láti gbogbo ilẹ̀ tí mo ti lé wọn kúrò ní ìgbà ìbínú àti ìkáàánú ńlá mi. Èmi yóò mú wọn padà wá sí ilẹ̀ yìí; èmi ó sì jẹ́ kí wọn ó máa gbé láìléwu.
38 Amasea, ilia da Na fi dunu esalumu. Amola, Na da ilia Gode esalumu.
Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi, èmi yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn.
39 Amola Na hamobeba: le, ilia hamomu hanai liligi da afadafa fawane ba: mu. Ilia da ili amola iligaga fi hahawane esaloma: ne, Nama fawane nodoma: ne hanai ba: mu.
Èmi ó fún wọn ní ọkàn kan àti ìṣe kí wọn kí ó lè máa bẹ̀rù mi fún rere wọn àti fún rere àwọn ọmọ wọn tí ó tẹ̀lé wọn.
40 Na da eso huluane dialoma: ne Gousa: su gaheabolo ilima hamomu. Na da eso huluane mae yolesili, hou ida: iwane fawane ilima hamomu. Amola Na da ilia dogo huluane amoga ilia da Nama beda: iwane nodoma: ne, amola bu eno hamedafa baligi fa: ma: ne agoane hamomu.
Èmi ò bá wọn dá májẹ̀mú ayérayé, èmi kò ní dúró láti ṣe rere fún wọn, Èmi ó sì jẹ́ kí wọ́n bẹ̀rù mi, wọn kì yóò sì padà lẹ́yìn mi.
41 Na da ilima hahawane hamonanebeba: le, Na amola da hahawane bagade ba: mu. Amola ilia da Isala: ili soge amo ganodini eso huluane esaloma: ne, Na da logo doasimu.
Lóòtítọ́, èmi ó yọ̀ nípa ṣíṣe wọ́n ní rere, èmi ó sì fi dá wọn lójú nípa gbígbìn wọ́n sí ilẹ̀ yìí tọkàntọkàn mi.
42 Na da ilima amo wadela: su huluane i dagoi. Amo defele, Na da liligi ida: iwane ilima ima: ne ilegei, amo huluane ilima imunu.
“Nítorí báyìí ni Olúwa wí, gẹ́gẹ́ bí èmi ti mú gbogbo ibi ńlá yìí wá sórí àwọn ènìyàn yìí, bẹ́ẹ̀ ni èmi ó mú gbogbo rere tí èmi ti sọ nípa tiwọn wá sórí wọn.
43 Wali amo fi dunu da ilia soge da hafoga: i wadela: i soge agoane ba: mu, amola amo ganodini dunu amola ohe da hame esalumu. Amola Ba: bilone dunu ilia fawane da amo soge gagumu. Be amo soge ganodini, dunu da bugili nasu sogebi amo bu bidi lalebe ba: mu.
Lẹ́ẹ̀kan sí i, pápá yóò di rírà ní ilẹ̀ yìí tí ìwọ ti sọ pé, ‘Ohun òfò ni tí kò bá sí ọkùnrin tàbí àwọn ẹran, nítorí tí a ti fi fún àwọn ará Babeli.’
44 Dunu da amo bidi lale, bidi lasu meloa da dunuga dio dedei, amola gobele legesu amoga ga: i amola ba: su dunu ilia ba: i dagoi ba: mu. Amo hou da Bediamini ea soge, moilai fonobahadi amo da Yelusaleme sisiga: sa, Yuda moilai, agolo soge moilai, agolo fonobahadi soge moilai amola Yuda gagoe (south) soge moilai, amo huluane amo ganodini ba: mu. Na da dunu fi ilia sogedafa amoga bu oule misunu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Wọn ó fi owó fàdákà ra oko, wọn yóò fi ọwọ́ sí ìwé, wọn ó dí pa pẹ̀lú ẹlẹ́rìí láti ilẹ̀ Benjamini àti ní ìlú kéékèèké tí ó yí Jerusalẹmu ká, àti ní ìlú Juda àti ní ìlú àwọn ìlú orí òkè, àti ni àwọn ẹsẹ̀ òkè, àti ní gúúsù, èmi ó mú ìgbèkùn wọn padà wá, ni Olúwa wí.”

< Yelemaia 32 >