< Aisaia 60 >

1 Fedege agoane, Yelusaleme, di wa: legadole, eso agoane diga: ma. Hina Gode Ea hadigi da dima hadigisa.
“Dìde, tànmọ́lẹ̀, nítorí ìmọ́lẹ̀ rẹ ti dé, ògo Olúwa sì ràdàbò ọ́.
2 Fifi asi gala eno da gasi dunasi amoga dedeboi dagoi ba: mu. Be Hina Gode Ea hadigi da dima hadigimu. Ea hadigi esalebe da dima dafulili lelumu.
Kíyèsi i, òkùnkùn bo ilẹ̀ ayé òkùnkùn biribiri sì wà lórí àwọn ènìyàn, ṣùgbọ́n Olúwa ràn bò ọ́ ògo rẹ̀ sì farahàn lórí i rẹ.
3 Fifi asi gala fi da dia hadigi ba: sea, dima gilisimusa: dawa: mu. Amola dia hou da hehebolo mabe galu defele, amo ba: sea, hina bagade ilia da dima gilisimusa: dawa: mu.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóò wá sí ìmọ́lẹ̀ rẹ, àti àwọn ọba sí ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ rẹ.
4 Hou wali hamonana, amo ba: ma: ne ba: le gagama. Dia fi dunu da buhagimusa: gilisisa. Dia gofelali da soge sedaga ganini buhagimu. Didiwi da mano fonobahadi defele, enoga ouga: ne, oule misunu ba: mu.
“Gbé ojú rẹ sókè, kí o sì wò. Gbogbo wọn ṣa ara jọ pọ̀, wọ́n sì wá sọ́dọ̀ rẹ; àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin yóò wá láti ọ̀nà jíjìn, àwọn ọmọ rẹ obìnrin ni a ó tọ́jú ní ẹ̀gbẹ́ rẹ.
5 Di da amo ba: sea, hahawane bagade ba: mu. Di da hahawane fofogadigiba: le, yagugumu. Bagade gagui fifi asi gala ilia liligi da dilima gaguli manebe ba: mu. Soge amo da hano wayabo bagade na: iyadodili diala, amoga ilia liligi noga: i dima gaguli manebe ba: mu.
Nígbà náà ni ìwọ yóò wò tí ojú rẹ yóò máa dán, ọkàn rẹ yó fò, yó sì kún fún ayọ̀; ọrọ̀ inú Òkun ni a ó kò wá sọ́dọ̀ rẹ, sí ọ̀dọ̀ rẹ ni ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè yóò wá.
6 Ga: mele dada: lesu bagade da Midia: ne amola Ifa amola Siba amoga gouli amola gabusiga: manoma liligi gaguli manebe ba: mu. Dunu da sia: ida: iwane gala amo Hina Gode Ea hamobe, amo fifi asi gala ilima hahawane adomu.
Ọ̀wọ́ ìbákasẹ yóò bo gbogbo ilẹ̀ rẹ, àwọn ọ̀dọ́ ìbákasẹ Midiani àti Efani. Àti gbogbo wọn láti Ṣeba yóò wá, wọn yóò mú wúrà àti tùràrí lọ́wọ́ tí wọn yóò sì máa kéde ìyìn Olúwa.
7 Gida amola Nebaiode dunu da ilia sibi huluane amo Hina Gode hahawane ba: ma: ne, ‘oloda’ da: iya gobele salimusa: dilima gaguli misunu. Hina Gode da Ea Debolo bu hahamomu. Amola ea gaheabolo hadigi da musa: hadigi baligi dagoi ba: mu.
Gbogbo agbo ẹran ìlú Kedari ni a ó kójọ sọ́dọ̀ rẹ, àwọn àgbò ti Nebaioti yóò sìn ọ́; wọn yóò jẹ́ ọrẹ ìtẹ́wọ́gbà lórí i pẹpẹ mi, bẹ́ẹ̀ ni n ó sì ṣe tẹmpili ògo mi lọ́ṣọ̀ọ́.
8 Na da adi liligi manebe ba: sala: ? Ilia da dusagai, amo da mu mobi hehenabe, amola “dafe” sio amo ea diasuga buhagisia hehenabe, agoai ba: sa.
“Ta ni àwọn wọ̀nyí tí ń fò lọ bí i kurukuru, gẹ́gẹ́ bí àwọn àdàbà sí ìtẹ́ wọn?
9 Ilia da dusagai amo da Gode Ea fi dunu soge sedaga esalu, amo ilia sogedafa amoga buhagimusa: , gaguli manebe ba: sa. Ilia da Hina Gode amo Ea Dio amoma nodomusa: , silifa amola gouli gaguli maha. Ilia da Isala: ili ilia Hadigi Gode (Ea hamobeba: le, osobo bagade fifi asi gala huluane da Ea fi ilima nodomu) Ema nodomusa: maha.
Lóòtítọ́ àwọn erékùṣù bojú wò mí; ní ìṣíwájú ni àwọn ọkọ̀ ojú omi Tarṣiṣi; mú àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ wá láti ọ̀nà jíjìn, pẹ̀lú fàdákà àti wúrà wọn, fún ti ọlá Olúwa Ọlọ́run rẹ, Ẹni Mímọ́ Israẹli, nítorí òun ti fi ohun dídára ṣe ó lọ́ṣọ̀ọ́.
10 Hina Gode da fedege agoane, Yelusaleme amoma amane sia: sa, “Ga fi dunu da dia gagoi bu gagumu, amola ilia hina bagade, ilia da dima hawa: hamosu dunu agoane ba: mu. Na da ougiba: le, dima se iasu. Be wali Na da Na asigi hou amola gogolema: ne olofosu dima olelemu.
“Àwọn àjèjì yóò tún ògiri rẹ mọ àwọn ọba wọn yóò sì sìn ọ́. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ní ìbínú ni mo lù ọ́, ní àánú èmi yóò ṣe inú rere sí ọ.
11 Fifi asi gala hina bagade ilia da dima ilia noga: i liligi gaguli misa: ne, dia logo ga: su da gasia amola esoga hamedafa ga: si ba: mu.
Gbogbo ẹnu-bodè rẹ ni yóò wà ní ṣíṣí sílẹ̀, a kì yóò tì wọ́n ní ọ̀sán àti ní òru, tó bẹ́ẹ̀ tí àwọn ọkùnrin yóò le è kó ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè wá tí àwọn ọba wọn yóò ṣáájú ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́ ìṣẹ́gun.
12 Be fifi asi gala amo ilia da dima hawa: hame hamosea, ilia da wadela: lesi dagoi ba: mu.
Nítorí pé orílẹ̀-èdè tàbí ilẹ̀ ọba tí kì yóò sìn ọ́ ni yóò parun; pátápátá ni yóò sì dahoro.
13 Ilia da ifa baligili noga: idafa amo “saibalase” amola ‘yuniba’ amola ‘baine’ amo Lebanone sogega, di Yelusaleme bu gagumusa: , amola Na Debolo Diasu bu noga: musa: , amola Na moilai hadigi lamusa: , gaguli misunu.
“Ògo Lebanoni yóò wá sí ọ̀dọ̀ rẹ, igi junifa, firi àti sípírẹ́ṣì papọ̀, láti bu ọlá fún ilé ìsìn mi; àti pé èmi yóò sì ṣe ibi ẹsẹ̀ mi lógo.
14 Dunu amo da musa: dima se iasu, amo ilia egefe da misini, ilia dilima nodosu olelema: ne, gududafa begudumu. Dunu da musa: dima higasu, ilia da dia emo gadenene midadili gudu gala: la sa: ili, dilima nodomu. Ilia da dima amane sia: mu, ‘Hina Gode Ea Moilai Bai Bagade’ amola ‘Saione da Isala: ili Fi ilia Hadigi Hina Gode, Ea Moilai Bai Bagade.’
Àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin àwọn apọ́nilójú rẹ yóò wá foríbalẹ̀ fún ọ; gbogbo àwọn tí ó ti kẹ́gàn rẹ ni wọn yóò tẹríba níwájú rẹ wọn yóò sì pè ọ́ ní ìlú Olúwa, Sioni ti Ẹni Mímọ́ Israẹli.
15 Di da moilai bai bagade yaloi dialu, amola dunu eno ilia da di higa: i. Di da wadela: lesi dagoi ba: i. Be amo hou fisili, Na da di afadenene, bu bagade amola noga: i ba: su amo di bu hahamomu. Amasea, di da eso huluane hahawane hou fawane ba: mu.
“Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a ti kórìíra rẹ, a sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀, láìsí ẹnìkan tí ó ń gba ọ̀dọ̀ rẹ kọjá, Èmi yóò ṣe ọ́ ní ìṣògo ayérayé àti ayọ̀ àtìrandíran.
16 Fifi asi gala amola hina bagade, ilia da ame da ea manoma dodo maga: me iaha, amo defele di asigiliwane ouligimu. Amola Na, Hina Gode, da dili gaga: i dagoi, amo dilia dawa: mu. Amola Isala: ili Gode Bagadedafa da di halegale masa: ne, dia se iasu diasu logo doasi dagoi, amo di da dawa: mu.
Ìwọ yóò mu wàrà gbogbo orílẹ̀-èdè a ó sì fun ọ́ ni ọmú àwọn ọba. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa, èmi ni Olùgbàlà rẹ, Olùdáǹdè rẹ, Alágbára ti Jakọbu.
17 Na da dia ‘balase’ lale, bu gouli noga: i amo dima gaguli misunu. Amola Na da dia ouli amola ifa lale bu silifa amola ‘balase’ noga: i dima gaguli misunu. Amola Na da dia igi lale bu ouli noga: i dima gaguli misunu. Dia ouligisu dunu da dima se bu hame imunu. Na hamobeba: le, ilia da moloidafa amola olofoiwane fofada: nanu, noga: le ouligimu.
Dípò idẹ, èmi ó mú wúrà wá fún ọ, dípò fàdákà èmi ó mú irin wá. Dípò igi yóò mú idẹ wá fún ọ, àti irin dípò òkúta. Èmi yóò fi àlàáfíà ṣe àwọn ìjòyè rẹ àti òdodo gẹ́gẹ́ bí alákòóso rẹ.
18 Dia da gegesu halasu bu hame nabimu. Dia soge da bu wadela: lesi hame ba: mu. Na da di ouligimu, amola gasa bagade gagoi ea gaga: i defele, di gaga: mu. Amola Na da di gaga: iba: le, dia da Nama nodomu.
A kì yóò gbọ́ nípa rògbòdìyàn ní ilẹ̀ rẹ mọ́, tàbí ìdahoro àti ìparun nínú agbègbè rẹ, ṣùgbọ́n ìwọ yóò pe ògiri rẹ ní ìgbàlà àti àwọn ẹnu-bodè rẹ ní ìyìn.
19 Eso da esomogoa hadigisa. Be amo esoga, eso da dima bu hame hadigimu amola gasia, oubi da dima bu hame hadigimu. Bai Na, Hina Gode da dima eso huluane hadigilalumu. Na gadodafa hadigi hou da dima hadigiwane dialumu.
Òòrùn kì yóò sì jẹ́ ìmọ́lẹ̀ rẹ ní ọ̀sán mọ́, tàbí kí ìtànṣán òṣùpá tún ràn sí ọ mọ́, nítorí Olúwa ni yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ rẹ ayérayé, àti Ọlọ́run rẹ yóò jẹ́ ògo rẹ.
20 Dia da: i diosu eso da dagomu. Na, Hina Gode da dima eso huluane hadigilalumu. Eso amola oubi amola da dagomu. Be Na hadigi da hamedafa dagomu.
Òòrùn rẹ kì yóò sì wọ̀ mọ́, àti òṣùpá rẹ kì yóò sì wọ òòkùn mọ́; Olúwa ni yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ ayérayé rẹ, àti àwọn ọjọ́ arò rẹ yóò sì dópin.
21 Dia fi dunu da hou moloidafa fawane hamomu amola ilia da eso huluane Isala: ili soge gagulalumu. Na da Na gasa bagade hou amoga Na fi hahamoi amola Isala: ili sogega ili bugi dagoi, dunu huluane da ba: mu.
Lẹ́yìn náà ni gbogbo àwọn ènìyàn rẹ yóò di òdodo àwọn ni yóò sì jogún ilẹ̀ náà títí ayé. Àwọn ni irúgbìn tí mo ti gbìn, iṣẹ́ ọwọ́ mi, láti fi ọláńlá mi hàn.
22 Amola dia baligili fonobahadidafa sosogo fi da alele, gasa bagade fifi asi gala defele ba: mu. Na ilegei eso da doaga: sea, Na da amo hedolowane hamomu. Na da Hina Gode!
Èyí tí ó kéré jù nínú yín yóò di ẹgbẹ̀rún kan, èyí tí ó kéré yóò di orílẹ̀-èdè ńlá. Èmi ni Olúwa; ní àkókò rẹ̀, Èmi yóò ṣe èyí kánkán.”

< Aisaia 60 >