< Yelemaia 16 >

1 Hina Gode da eno nama amane sia: i,
Bákan náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
2 “Di amo soge ganodini, uda mae lama amola mano mae lalelegema!
“Ìwọ kò gbọdọ̀ ní ìyàwó, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ ní ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin níbí yìí.”
3 Mano amo da guiguda: lalelegesea amo ilia hou, amola ilia ada amola ame ilia hou, Na da dima olelemu.
Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa wí nípa ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin tí wọ́n bá bí nílẹ̀ yìí, àti ìyá tí ó bí wọn àti baba wọn.
4 Ilia da olo bagade madelale, bogogia: mu. Amola dunu eno da iliba: le hame didigia: mu amola ilia da: i hodo hame uli dogonesimu. Be ilia da: i hodo da iga gialegei bi heda: i defele osoboga dialebe agoai ba: mu. Ilia da gegesu ganodini o ha: i bagade ganodini bogogia: mu, amola ilia da: i hodo da sio fi amola sigua ohe amo ilia ha: i manu agoane ba: mu.
“Wọn yóò kú ikú ààrùn, wọn kò ní sin wọ́n tàbí ṣọ̀fọ̀ fún wọn. Wọn ó dàbí ìdọ̀tí lórí ilẹ̀; wọn ó ṣègbé pẹ̀lú idà àti ìyàn. Òkú wọn yóò sì di oúnjẹ fún ẹyẹ ojú ọ̀run àti ẹranko ilẹ̀.”
5 Diasu amo ganodini dunu ilia didigia: su, amo ganodini mae golili sa: ima. Dunu da bogosea, dia mae dawa: ma amola mae dima. Bai Na da wali Na fi dunuma hahawane olofosu hou amola asigi hou bu hamedafa imunu.
Nítorí báyìí ni Olúwa wí: “Má ṣe wọ ilé tí oúnjẹ ìsìnkú wà, má ṣe lọ síbẹ̀ láti káàánú tàbí ṣọ̀fọ̀, nítorí mo ti mú àlàáfíà, ìfẹ́ àti àánú mi kúrò lórí àwọn ènìyàn wọ̀nyí,” ni Olúwa wí.
6 Bagade gagui dunu amola hame gagui dunu, da amo soge ganodini gilisili bogogia: mu. Be eno dunu da ilima asigiba: le, hame didigia: mu amola ilia da: i hodo hame uli dogonesimu. Dunu eno da ilia da: i dioi olelema: ne, ilia da: i hame fafa: ginisimu amola ilia dialuma hinabo hame waga: mu.
“Àti ẹni ńlá àti kékeré ni yóò ṣègbé ní ilẹ̀ yìí, wọn kò ní sin wọ́n tàbí ṣọ̀fọ̀ wọn, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹni tí yóò fá irun orí wọn nítorí wọn.
7 Dunu da ea dogolegei fi dunu da bogobeba: le, da: i diosea, dunu afae eno da ea dogo denesima: ne, ema ha: i amola waini hano naha, hamedafa gilisili fimu. Nowa dunu da ea ame o ada bogosea, dunu eno da ema asigi hou hamedafa olelemu.
Kò sí ẹni tí yóò fi oúnjẹ tu àwọn tí í ṣọ̀fọ̀ nínú, kódà kì í ṣe fún baba tàbí fún ìyá, kì yóò sí ẹni tí yóò fi ohun mímu tù wọ́n nínú.
8 Dunu eno da diasu ganodini lolo nasea, di da amo ha: i moma: ne gilisimusa: amo diasuga maedafa golili sa: ima.
“Ìwọ kò gbọdọ̀ lọ sí ilé tí àjọyọ̀ wà, má ṣe jókòó jẹun tàbí mu ohun mímu.
9 Na da Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili fi ilia Gode! Na sia: nabima! Hahawane sia: amola uda lasu lolo nabe hahawane sia: huluane amo ouiya: ma: ne Na da hamomu. Amo fi dunu guiguda: esalebe da amo hou doaga: i dagoi ba: mu.
Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run àwọn ọmọ Israẹli wí, Ní ojú yín ní ọjọ́ yín ni òpin yóò dé bá ìró ayọ̀ àti ìdùnnú, àti sí ohùn ìyàwó àti ọkọ ìyàwó ní ibí yìí.
10 Di da amo sia: Na fi dunuma olelesea, ilia da Hina Gode da abuliba: le se iasu bagadedafa ilima iaha, dima adole ba: mu. ‘Ninia da adi wadela: i hou hamobela: amola ninia Hina Godema adi wadela: i hou hamobela: ?’ ilia da amane adole ba: mu.
“Nígbà tí o bá sọ nǹkan wọ̀nyí fún àwọn ènìyàn yìí, tí wọ́n bá sì bi ọ́ wí pé, ‘Èéṣe tí Olúwa ṣe mú búburú yìí bá wa? Kí ni àṣìṣe tí àwa ṣe? Kín ni ẹ̀ṣẹ̀ tí àwa ṣẹ̀ sí Olúwa Ọlọ́run wa?’
11 Amasea, dia Hina Gode Ea sia: ilima amane alofele ima, ‘Dilia aowalalia da Na fisili, eno ogogosu ‘gode’ ilima sia: ne gadosu amola hawa: hamosu. Ilia da Na fisili, Na olelesu hamedafa nabawane hamosu.
Nígbà náà ni ìwọ yóò sọ fún wọn wí pé, ‘Nítorí tí àwọn baba yín ti kọ̀ mí sílẹ̀,’ ni Olúwa wí, ‘tí wọ́n sì tẹ̀lé àwọn òrìṣà mìíràn tí wọ́n ń bọ, tí wọ́n ń sìn, wọ́n kọ̀ mí sílẹ̀ wọn kò sì tẹ̀lé òfin mi mọ́.
12 Be dilia da dilia aowalalia ilia wadela: i hou baligili hamoi. Dilia huluane da dogo ga: nasi hamoi, amola wadela: idafa hou hamosu, amola Na sia: nabimu hame dawa:
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti ṣe búburú ju ti àwọn baba yín lọ. Wò ó bí gbogbo yín ṣe ń rìn, olúkúlùkù yín nínú agídí ọkàn búburú rẹ̀, dípò kí ẹ fi gbọ́ tèmi.
13 Amaiba: le Na da dili amo sogega fisili masa: ne, sefasisia, dilia da eno soge, dilia amola dilia aowalalia hame dawa: soge amoga mugululi masunu. Amola amogawi, dilia esoga amola gasia, eno ogogosu ‘gode’ ilia hawa: hamonanu. Amola Na da dilima asigi hou hame olelemu.’”
Èmi yóò gbé yin kúrò ní ilẹ̀ yìí lọ sí ilẹ̀ tí baba yín tàbí ẹ̀yin kò mọ̀ rí, níbẹ̀ ni ẹ̀yin yóò ti máa sìn ọlọ́run kéékèèké ní ọ̀sán àti òru nítorí èmi kì yóò fi ojúrere wò yín.’
14 Hina Gode da amane sia: sa, “Na da Gode esala. Amola Na da Isala: ili fi dunu Idibidi sogega fisili masa: ne, ga oule asi. Be eso da misunu amoga, Na fi dunu da amo hou Na hamobeba: le, amoga ilia sia: bu hame ilegemu.
“Nítorí náà, ọjọ́ náà ń bọ̀ wá,” ni Olúwa wí, “tí àwọn ènìyàn kò ní sọ pé, ‘Dájúdájú Olúwa wà láààyè Olúwa ń bẹ, Ẹni tí ó mú Israẹli jáde kúrò ní Ejibiti.’
15 Be Na da Na fi dunu gagoe (north) soge amola eno fifi asi gala ilia sogega afagogoi. Amola Na da ili amo soge Na da ilia aowalalia amoga i, ilima bu oule misunuba: le, ilia da Na da Gode esala ili buhagima: ne logo doasi dagoi, amo hou dafawaneyale dawa: beba: le, ilia da amo sia: ga dafawane hamoma: ne ilegemu. Na, Hina Gode da sia: i dagoi.”
Ṣùgbọ́n wọn yóò sọ wí pé, ‘Bí Olúwa ṣe wà nítòótọ́ tí ó mú àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ àríwá àti ní gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó ti lé wọn.’ Bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò dá wọn padà sí ilẹ̀ tí mo fún àwọn baba ńlá wọn.
16 Hina Gode da amane sia: sa, “Na da menabo gasa: su dunu bagohame amo Na fi dunu gasa: ma: ne, ilima misa: ne sia: mu. Amasea, Na da benea ahoasu dunu bagohame, goumi amola agolo amola magufu gelabo huluane amoga Na fi dunu lama: ne, ilima misa: ne sia: mu.
“Ṣùgbọ́n báyìí, Èmi yóò ránṣẹ́ sí àwọn apẹja púpọ̀,” ni Olúwa wí. “Wọn ó sì dẹ wọ́n lẹ́yìn èyí yìí èmi yóò ránṣẹ́ sí àwọn ọdẹ púpọ̀, wọn yóò dẹ wọ́n lórí gbogbo òkè ńlá àti òkè gíga, àti ní gbogbo pálapàla àpáta.
17 Na da ilia wadela: i hamobe huluanedafa ba: lala. Na mae ba: ma: ne wamolegemu da hamedei.
Ojú mi wà ní gbogbo ọ̀nà wọn, wọn kò pamọ́ fún mi bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀ṣẹ̀ wọn kò fi ara sin lójú mi.
18 Ilia wadela: i hou hamobeba: le, Na da ilima baligili se imunu. Bai ilia da Na soge amo ganodini hame esala (bogoi ea da: i hodo defele) loboga hamoi ogogosu ‘gode’ amoga nabaiba: le, Na soge da ledodafa hamoi dagoi ba: sa.”
Èmi yóò san ẹ̀san ìwà búburú àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn fún wọn ní ìlọ́po méjì, nítorí wọ́n ti ba ilẹ̀ mi jẹ́ pẹ̀lú àwọn ère wọn aláìlẹ́mìí, wọ́n sì fi òkú àti ohun ẹ̀gbin àti ìríra wọn kún ilẹ̀ ìní mi.”
19 Hina Gode! Di fawane da na gaga: sa amola nama gasa iaha. Dia da bidi hamosu eso amoga na fidilala. Fifi asi gala fi dunu da osobo bagade bega: bega: nini Dima misini, amane sia: mu, ‘Ninia aowalalia da ogogosu ‘gode’ amola hamedei loboga hamoi ‘gode’ agoaila fawane gagui.’
Olúwa, alágbára àti okun mi, ẹni ààbò mi ní ọjọ́ ìpọ́njú, àwọn orílẹ̀-èdè yóò wá láti òpin ayé wí pé, “Àwọn baba ńlá wa kò ní ohun kan bí kò ṣe ẹ̀gbin òrìṣà, ìríra tí kò dára fún wọn nínú rẹ̀.
20 Dunu ilisu da ilila: ‘gode’ hamomu defele ganabela: ? Hame mabu! Amai ganiaba, amo liligi da ‘godedafa’ hame ba: la: loba.”
Ṣé àwọn ènìyàn lè dá Ọlọ́run fún ara wọn bí? Bẹ́ẹ̀ ni, ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí kì í ṣe Ọlọ́run.”
21 Hina Gode da amane sia: sa, “Amaiba: le, Na da wali fifi asi gala huluane ilima Na gasa bagade hou olelemu. Amasea, Na da Hina Godedafa, amo ilia da dawa: mu.”
“Nítorí náà, Èmi yóò kọ́ wọn ní àkókò yìí, Èmi yóò kọ́ wọn pẹ̀lú agbára àti títóbi mi. Nígbà náà ni wọn ó mọ pé orúkọ mi ní Olúwa.

< Yelemaia 16 >