< Esela 1 >

1 Ode bisili amoga Sailase da Besia soge ouligisu, Hina Gode Ea balofede (Gode Sia: Alofesu dunu) Yelemaiama musa: sia: i liligi da amo defele doaga: i dagoi ba: i. E da Sailase ea asigi dawa: su olelebeba: le, Sailase da ea fidisu dunuma ilia da sia: amo dedene, ea soge amo ganodini dunu huluane nabima: ne idili ima: ne sia: i. Ea sia: da agoane dedei,
Ní ọdún kìn-ín-ní Kirusi, ọba Persia, kí a lè mú ọ̀rọ̀ Olúwa tí Jeremiah sọ ṣẹ, Olúwa ru ọkàn Kirusi ọba Persia sókè láti ṣe ìkéde jákèjádò gbogbo agbègbè ìjọba rẹ̀, kí ó sì ṣe àkọsílẹ̀ rẹ̀ pé,
2 “Na, Sailase, Besia hina bagade da dilima sia: sa. Hina Gode, Hebene amoga Hina esala, amo da na osobo bagade fifi asi gala huluane ilima hina esaloma: ne hamoi dagoi. Amola E da na Yelusaleme moilai bai bagadega Ea Debolo diasu gaguma: ne sia: i.
“Èyí ni ohun tí Kirusi ọba Persia wí pé: “‘Olúwa, Ọlọ́run ọ̀run, ti fún mi ní gbogbo ìjọba ayé. Ó sì ti yàn mí láti kọ́ tẹmpili Olúwa fún un ní Jerusalẹmu tí ó wà ní Juda.
3 Gode da dilia Ea hou lalegagui dunu huluane noga: le fidimu da defea. Dilia Yelusaleme moilai bai bagade amoga asili, Hina Gode Ea Debolo diasu mugului amo bu gaguma. Hina Gode da Isala: ili dunu ilia Gode amola ilia da Yelusaleme amo ganodini, Ema nodone sia: ne gadolala.
Ẹnikẹ́ni nínú àwọn ènìyàn rẹ̀ láàrín yín—kí Ọlọ́run rẹ̀ wà pẹ̀lú rẹ̀, kí ó sì gòkè lọ sí Jerusalẹmu tí ó wà ní Juda, láti kọ́ tẹmpili Olúwa Ọlọ́run Israẹli, Ọlọ́run tí ó wà ní Jerusalẹmu.
4 Gode Ea fi dunu ilia gadenene fi na: iyado dunu da mugululi asi dunu ilia masa: ne logo fidimu da defea. Ilia da silifa, gouli amola ohe fi ilia liligi gaguli masa: ne amola ilima imunu da defea. Amola Gode Ea Debolo diasu amo ganodini, Godema ima: ne liligi ilima imunu da defea.”
Kí àwọn ènìyàn ní ibikíbi tí ẹni náà bá ń gbé kí ó fi fàdákà àti wúrà pẹ̀lú ohun tí ó dára àti ẹran ọ̀sìn, pẹ̀lú ọrẹ àtinúwá ràn án lọ́wọ́ fún tẹmpili Ọlọ́run ní Jerusalẹmu.’”
5 Amalalu, Yuda fi bisilua dunu, Bediamini fi bisilua dunu, gobele salasu dunu, Lifai fi dunu amola dunu eno huluane amo Gode da ilia dogoga sia: i dunu, ilia da Yelusalemega Hina Gode Ea Debolo diasu gagumusa: masa: ne, liligi momagei dagoi.
Nígbà náà àwọn olórí ìdílé Juda àti Benjamini àti àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi—olúkúlùkù ẹni tí Ọlọ́run ti fọwọ́ tọ́ ọkàn rẹ̀—múra láti gòkè lọ láti kọ ilé Olúwa ní Jerusalẹmu.
6 Ilia na: iyado dunu da ili fidi. Ilia da ilima liligi bagohame iasu. Ilia da silifa yaeya, gouli, ha: i manu, ohe fi ilia liligi gaguli masa: ne amola noga: i liligi eno Debolo ganodini Godema ima: ne liligi, ilima iasu.
Gbogbo àwọn aládùúgbò wọn ràn wọ́n lọ́wọ́ pẹ̀lú ohun èlò ti fàdákà àti wúrà, pẹ̀lú onírúurú ohun ìní àti ẹran ọ̀sìn àti pẹ̀lú àwọn ẹ̀bùn iyebíye, ní àfikún si gbogbo àwọn ọrẹ àtinúwá.
7 Musa: , hina bagade Nebiuga: denese da amo gouli, silifa amola ofodo amo lale, hina: ogogosu ‘gode’ ilia debolo diasu ganodini salasu. Sailase da amo liligi lale, Yu dunuma bu i.
Ní àfikún, ọba Kirusi mú àwọn ohun èlò tí ó jẹ́ ti ilé Olúwa jáde wá, tí Nebukadnessari ti kó lọ láti Jerusalẹmu tí ó sì ti kó sí ilé òrìṣà rẹ̀.
8 Sailase da liligi huluane gaguli misini, Besia muni ouligisu dunu Midilida: de ema i. Midilida: de da amo liligi dedenanu, Yuda ouligisu dunu amo Sesebaisa ema i.
Kirusi ọba Persia pàṣẹ fún Mitredati olùṣọ́ ilé ìṣúra láti kó wọn jáde, ó sì kà wọ́n fún Ṣeṣbassari ìjòyè Juda.
9 Liligi idi da agoane gala, Gouliga hamoi ofodo (Godema iabe salasu) ...30 Silifaga hamoi ofodo (Godema iabe salasu) ...1,000 Ofodo eno...29 Gouli ofodo fonobahadi...30 Silifa ofodo fonobahadi...410 Eno sasali liligi...1,000
Èyí ni iye wọn. Ọgbọ̀n àwo wúrà 30 Ẹgbẹ̀rún àwo fàdákà 1,000 Àwo ìrúbọ fàdákà mọ́kàndínlọ́gbọ̀n 29
Ọgbọ̀n àdému wúrà 30 Irinwó ó lé mẹ́wàá oríṣìí àdému fàdákà mìíràn 410 Ẹgbẹ̀rún kan àwọn ohun èlò mìíràn 1,000
11 Amo liligi huluane gilisili da gouli amola silifa ofodo, amola sasali liligi eno 5400 agoane. Sesebaisa amola mugululi asi dunu eno da Ba: bilone fisili, Yelusalemega asili, ilia da amo liligi gaguli asi.
Gbogbo ohun èlò wúrà àti ti fàdákà ní àpapọ̀ jẹ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún ó lé irinwó. Ṣeṣbassari kó gbogbo àwọn nǹkan wọ̀nyí wá pẹ̀lú àwọn ìgbèkùn tí ó gòkè wá láti Babeli sí Jerusalẹmu.

< Esela 1 >