< Nihemaia 1 >

1 Amo sia: da Nihemaia (Ha: galaia egefe) amo ea hawa: hamosu olelesa. Adasegesisi da Besia soge amoga hina bagade esalu. Ea ouligisu hou ode20 amola oubi ea dio Gisilefe amoga, na, Nihemaia, na da Besia bisili moilai bai bagade amo Susa, amo ganodini esalebe ba: i.
Ọ̀rọ̀ Nehemiah ọmọ Hakaliah. Ní oṣù Kisleu ní ogún ọdún (ìjọba Ahaswerusi ọba Persia) nígbà tí mo wà ní ààfin Susa,
2 Na olalali afae amo ea dio Hana: inai, e amola eno dunu gilisili da Yuda soge fisili, nama doaga: i. Na da Yelusaleme moilai bai bagade ea hou, amola ninia Yu fi musa: mugululi asi, Yuda sogega buhagi, amo ilia hou ilima adole ba: i.
Hanani, ọ̀kan nínú àwọn arákùnrin mi wá láti Juda pẹ̀lú àwọn ọkùnrin kan, mo sì béèrè lọ́wọ́ wọn nípa àwọn Júù tí ó ṣẹ́kù tí wọn kò kó ní ìgbèkùn, àti nípa Jerusalẹmu.
3 Ilia da amo hou nama adole i. Musa: mugululi asi dunu mogili da bogoi dagoi. Be mogili da buhagili, Yuda soge ganodini esala, da se bagade nabawane esala. Ga fi dunu gadenene esala da Yu dunu amo higale ba: sa, ilia sia: i. Yelusaleme gagoi dobea amo musa: mugululi sa: i dagoi, amo da bu hame gagoi. Amola logo ga: su musa: laluga nei, amo da bu hame ga: si.
Wọ́n sọ fún mi pé, “Àwọn tí ó kù tí a kó ní ìgbèkùn tí wọ́n sì padà sí agbègbè ìjọba wà nínú wàhálà púpọ̀ àti ẹ̀gàn. Odi Jerusalẹmu ti wó lulẹ̀ a sì ti fi iná sun ẹnu ibodè rẹ̀.”
4 Na da amo sia: nababeba: le, fila sa: ili amola bagadewane dinanu. Eso didia amoga, na da dinanuwane, ha: i mae nawane Godema sia: ne gadolalu.
Nígbà tí mo gbọ́ àwọn nǹkan wọ̀nyí, mo jókòó mo sì sọkún. Mo ṣọ̀fọ̀, mo gbààwẹ̀, mo sì gbàdúrà fún ọjọ́ díẹ̀ níwájú Ọlọ́run ọ̀run.
5 Na da amane sia: ne gadoi, “Hina Gode Hebene ganodini esala! Di da bagadedafa amola ninia Diba: le beda: i bagade. Dia gousa: su, amo Di da Dima asigi amola nabasu dunu amo fidima: ne hamoi, amo Di da mae fisili dawa: lala.
Nígbà náà ni mo wí pé: “Olúwa, Ọlọ́run ọ̀run, Ọlọ́run tí ó tóbi tí ó sì ní ẹ̀rù, tí ó ń pa májẹ̀mú ìfẹ́ rẹ̀ mọ́ pẹ̀lú wọn tí ó fẹ́ ẹ tí wọ́n sì ń pa àṣẹ mọ́.
6 Hina Gode! Na hou ba: ma amola na sia: ne gadosu nabima! Na da dia fi dunu amo Isala: ili fi dunu amola uda, na da gasi huluane amola eso huluane amoga ili fidima: ne, Dima sia: ne gadolala. Dafawane! Ninia Isala: ili dunu da wadela: le hamoi dagoi. Na amola na aowalali dunu da wadela: i hou hamoi dagoi.
Jẹ́ kí etí rẹ kí ó ṣí sílẹ̀, kí ojú ù rẹ kí ó sì ṣí sílẹ̀ láti gbọ́ àdúrà tí ìránṣẹ́ rẹ ń gbà ní iwájú rẹ ní ọ̀sán àti ní òru fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ènìyàn Israẹli. Mo jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ àwa ọmọ Israẹli àti tèmi àti ti ilé baba mi, tí a ti ṣẹ̀ sí ọ.
7 Ninia da Dima wadela: i hou hamosu, amola Dia sia: hame nabasu. Ninia Dia sema amo Di da dia hawa: hamosu dunu Mousese ea lafidili ninima i, amoma hame fa: no bobogesu.
Àwa ti ṣe búburú sí ọ. A kò sì pa àṣẹ ìlànà àti òfin tí ìwọ fún Mose ìránṣẹ́ rẹ mọ́.
8 Dia da Mousesema sia: i liligi bu dawa: ma, amane, ‘Dilia Isala: ili dunu da Na sia: hame nabasea, Na da dilia fi afagogole, ga fi dunu amo ganodini esaloma: ne sefasimu.
“Rántí ìlànà tí o fún Mose ìránṣẹ́ rẹ, wí pé, ‘Bí ìwọ bá jẹ́ aláìṣòótọ́, èmi yóò fọ́n yín ká sí àárín àwọn orílẹ̀-èdè.
9 Be amasea, dilia da Nama, Na dilima hamoma: ne sia: i defele Nama bu sinidigisia, Na da dili soge amoga Nama nodone sia: ne gadomusa: Na da ilegei, amo sogega Na da dili bu oule misunu,’ Di da amane sia: i dagoi.
Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin bá yípadà sí mi, tí ẹ bá sì pa àṣẹ mi mọ́, nígbà náà bí àwọn ènìyàn yín tí a kó ní ìgbèkùn tilẹ̀ wà ní jìnnà réré ìpẹ̀kun ọ̀run, èmi yóò kó wọn jọ láti ibẹ̀, èmi yóò sì mú wọn wá, sí ibi tí èmi ti yàn bí i ibùgbé fún orúkọ mi.’
10 Hina Gode! Amo dunu da Dia hawa: hamosu dunu! Ilia da Dia ilegei fi dunu! Di da Dia gasa bagade amoga, amo fi dunu gaga: i dagoi.
“Àwọn ni ìránṣẹ́ rẹ àti ènìyàn rẹ àwọn tí ìwọ rà padà pẹ̀lú agbára ńlá rẹ àti ọwọ́ agbára ńlá rẹ.
11 Amaiba: le, na sia: ne gadosu amola Dia hawa: hamosu dunu eno ilia Dima nodomusa: dawa: , ilia sia: ne gadosu amola nabima. Hina bagade da na sia: noga: le nabima: ne, Di da ea dogo ganodini hawa: hamoma!” na amane sia: ne gadoi. Amo esoga na da Besia hina bagade amo ea waini hano iasu dunu esalu.
Olúwa, jẹ́ kí etí rẹ ṣí sílẹ̀ sí àdúrà ìránṣẹ́ rẹ yìí, àti sí àdúrà àwọn ìránṣẹ́ rẹ tí wọ́n ní inú dídùn láti bọ̀wọ̀ fún orúkọ rẹ. Fún ìránṣẹ́ rẹ ní àṣeyọrí lónìí kí o sì síjú àánú wò ó níwájú ọkùnrin yìí.” Nítorí tí mo jẹ́ agbọ́tí ọba nígbà náà.

< Nihemaia 1 >