< Eseda 1 >

1 Besia eagene hina bagade ea dio amo Segesisi da moilai bai bagade amo Susa, amo ganodini ea ouligisu hawa: hamonanu. E da soge fi hihi 127 agoane ouligisu. Amo soge fi hihi da Inidia soge asili Suda: ne soge amo ganodini esalu.
Èyí ni ohun tó ṣẹlẹ̀ ní ìgbà Ahaswerusi, tí ó jẹ ọba lórí ẹ̀tàdínláàdóje ìletò bẹ̀rẹ̀ láti India títí ó fi dé Etiopia.
2
Ní àkókò ìgbà náà ọba Ahaswerusi ń ṣe ìjọba ní orí ìtẹ́ ẹ rẹ̀ ní ilé ìṣọ́ ti Susa,
3 Ode osodayale ea ouligisu ganodini, e da lolo mai. E da ea lolo manusa: , eagene ouligisu dunu, soge fi hihi ilia ouligisu amola hina dunu, Besia dadi gagui dunu amola Midia dadi gagui dunu, amo huluane hiougi.
ní ọdún kẹta ìjọba rẹ̀, ó ṣe àsè fún gbogbo àwọn ọlọ́lá àti ìjòyè. Àwọn olórí ológun láti Persia àti Media, àwọn ọmọ-aládé, àti àwọn ọlọ́lá ìletò wà níbẹ̀ pẹ̀lú.
4 E da oubi gafeyale amoga e da ea diasu amola Susa moilai amo liligi noga: idafa amo hiougi misi dunu ilima olelesa lalalu.
Ó ṣe àfihàn púpọ̀ ọrọ̀ ìjọba rẹ̀ àti dídán àti ògo ọláńlá rẹ̀ fún ọgọ́sàn-án ọjọ́ gbáko.
5 Amalalu, hina bagade da lolo nasu bagade, amo ea diasu gagoi ganodini hamoi. Amo hamonana hi afae galagai, amola amoga misa: ne, e da dunu huluane, bagade gagui amola hame gagui, amo huluane hiougi.
Nígbà tí ọjọ́ wọ̀nyí kọjá, ọba ṣe àsè fún ọjọ́ méje, nínú ọgbà tí ó wà nínú àgbàlá ààfin ọba, gbogbo ènìyàn láti orí ẹni tí ó kéré dé orí ẹni tí ó lọ́lá jùlọ, tí wọ́n wà ní ilé ìṣọ́ ti Susa.
6 Hina bagade ea gagoi da nina: hamoi noga: idafa ba: i. Gasiga: su abula da haisewe amola ahea: iai ba: i. Ilia da oga: iya: i efe amoga silifa gedu amoga la: gilisili amola igi ogelu duni bugi ili amoga gosagisi. Iluwa: su fafai amo da gouli amola silifa amoga hamoi da gagoi ganodini ligisi dialebe ba: i, amola gagoi da ogelu amola yoi gele noga: idafa amola su ela: mei amola ela: mei haisewe igi, amoga fa: i.
Ọgbà náà ní aṣọ fèrèsé funfun àti aláwọ̀ òféfèé. Àwọn okùn tí a fi aṣọ aláwọ̀ funfun àti aláwọ̀ elése àlùkò rán ni a fi ta á mọ́ òrùka fàdákà lára àwọn òpó mabu. Àwọn ibùsùn tí a fi wúrà àti fàdákà ṣe wà níbi pèpéle òkúta tí a fi ń tẹ́lẹ̀ ilé tí ó jẹ́ mabu, píálì àti òkúta olówó iyebíye mìíràn.
7 Waini hano moma: ne, ilia da gouli faigelei hisu hisu hahamoi amo ganodini soga: sasali. Hina bagade da ea waini nodone bagade sagoi.
Kọ́ọ̀bù wúrà onídìí-odó ni a fi ń bu wáìnì fún wọn mu, ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn sì yàtọ̀ sí èkejì, wáìnì ọba pọ̀ púpọ̀, gẹ́gẹ́ bí ọba ṣe lawọ́ sí.
8 Hina bagade da ea hawa: hamosu dunu ilima ilia da mae hihini dunu huluane ilia waini hano manusa: defele ilima ima: ne sia: i.
Gẹ́gẹ́ bí àṣẹ ọba a fi ààyè gba àlejò kọ̀ọ̀kan láti mu tó bí ó bá ti fẹ́, nítorí ọba ti pàṣẹ fún gbogbo àwọn ti ń bu wáìnì láti bù fún ẹnìkọ̀ọ̀kan bí wọ́n bá ṣe béèrè fún mọ.
9 Amo galu, hina bagade uda Fa: sedai da hina bagade diasu ganodini, lolo manusa: uda fawane hiougi.
Ayaba Faṣti náà ṣe àsè fún àwọn obìnrin ní ààfin ọba Ahaswerusi.
10 Lolo nabe eso fesuga, hina bagade da waini nanu amola hahawane ba: su. Amalalu, e da ea gulusu danai hawa: hamosu dunu fesuale gala amo ema misa: ne sia: i. Ilia dio da Mihiuma: ne, Bisida, Habouna, Bigida, Aba: geda, Sida amola Gaga: se.
Ní ọjọ́ keje, nígbà tí wáìnì mú inú ọba dùn, ó pàṣẹ fún Mehumani, Bista, Harbona, Bigta àti Abagta, Setari àti Karkasi, àwọn ìwẹ̀fà méje tí ń jíṣẹ́ fún Ahaswerusi.
11 E da amo dunu ilia da hina bagade uda Fa: sedai amo habuga ea dialumaga figisili, ema oule misa: ne sia: i. Fa: sedai da uda noga: idafa ba: su. Hina bagade da Fa: sedai ea noga: idafa ba: su, amo ea hiougi dunuma olelemusa: dawa: i galu.
Kí wọn mú ayaba Faṣti wá síwájú rẹ̀, ti òun ti adé ọba rẹ̀, kí ó lè wá fi ẹwà rẹ̀ hàn àwọn ènìyàn àti àwọn ọlọ́lá, nítorí tí ó rẹwà.
12 Be hawa: hamosu dunu da ema hina bagade ea hamoma: ne sia: i olelebeba: le, Fa: sedai hihini hame misunu sia: i. Hina bagade da amo sia: nababeba: le, ougi bagade ba: i.
Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn ìránṣẹ́ jẹ́ iṣẹ́ ọba, ayaba Faṣti kọ̀ láti wá. Nígbà náà ni ọba bínú gidigidi, ìbínú náà sì pọ̀ jọjọ.
13 Hina bagade ea hou da bagade dawa: su dunuma, abuli hamoma: beyale adole ba: su. Amaiba: le, e da ea fada: i sia: ne iasu dunuma ilia sia: nabimusa: wele sia: i.
Gẹ́gẹ́ bí ìṣe rẹ̀ ní ìgbà gbogbo, ọba máa ń béèrè ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ àwọn tí ó ní ìmọ̀ òfin àti ìdájọ́, ó sọ ọ́ fún àwọn amòye tí wọ́n mòye àkókò,
14 Hina bagade ea fada: i sia: ne iasu ouligisu dunu mimogo fesuale gala, Besia amola Midia soge ganodini ilia dio da Gasina, Sieda, A:damada, Dasisi, Milese, Ma: sina, amola Mimiuga: ne.
àwọn tí wọ́n súnmọ́ ọba àwọn wọ̀nyí ni Karṣina, Ṣetari, Admata, Tarṣiṣi, Meresi, Marsena àti Memukani, àwọn ọlọ́lá méje ti Persia àti Media tí wọ́n ṣe pàtàkì sí ọba, wọ́n sì tún wà ní ibi gíga ní ìjọba.
15 E da amo dunuma amane sia: i, “Na da hina bagade Segesisi! Ni da na hawa: hamosu dunuma ilia da na uda Fa: sedai e da nama oule misa: ne adosi. Be e da na sia: nabimu higa: i. Ninia da ema adi hamoma: bela: ? Sema dedei da adi sia: sala: ?”
Ó béèrè pé, “Kí ni a lè ṣe sí ayaba Faṣti gẹ́gẹ́ bí òfin? Nítorí kò tẹríba fún àṣẹ ọba Ahaswerusi tí àwọn ìwẹ̀fà ọba sọ fún un.”
16 Amalalu, Mimiuga: ne da hina bagade amola eagene ouligisu dunu ilima amane sia: i, “Hina bagade uda Fa: sedai da hina bagade ema fawane hame gadele sia: i. Be e da eagene ouligisu dunu huluane amola dunu huluane Besia amola Midia soge ganodini, amo huluane ilima gadele sia: i dagoi.
Memukani sì dáhùn níwájú ọba àti àwọn ọlọ́lá pé, “Ayaba Faṣti ti ṣe búburú, kì í ṣe sí ọba nìkan ṣùgbọ́n sí gbogbo àwọn ọlọ́lá àti àwọn ènìyàn tí ó wà ní gbogbo agbègbè ilẹ̀ ọba Ahaswerusi.
17 Bai uda huluane hina bagade ea ouligisu fifi asi gala amo ganodini da Fa: sedai ea hihi sia: nababeba: le, ilia da egoama hihi ba: mu. Ilia da amane sia: mu, ‘Hina bagade Segesisi da ea uda Fa: sedai ema misa: ne sia: i, be e da higa: i.’
Nítorí ìwà ayaba yìí yóò tàn dé ọ̀dọ̀ gbogbo àwọn obìnrin, tó bẹ́ẹ̀ tí ọkọ wọn yóò di gígàn lójú u wọn, wọn yóò sì sọ pé, ọba Ahaswerusi pàṣẹ pé kí á mú ayaba Faṣti wá síwájú òun, ṣùgbọ́n ó kọ̀ láti wá.
18 Besia amola Midia ouligisu dunu ilia uda da amo hou nababeba: le, ilia da wali eso, amo hame nabasu hou ilia egoama olelemu. Uda huluane da ilia egoama hame dogolegemu, amola egoa ilia da idua ilima ougi ba: mu.
Ní ọjọ́ yìí gan an ni àwọn ọlọ́lá obìnrin Persia àti ti Media tí wọ́n ti gbọ́ nípa ìwà ayaba wọn yóò ṣe bẹ́ẹ̀ sí gbogbo àwọn ìjòyè ọba bákan náà. Àfojúdi àti àìnírẹ́pọ̀ tí kò lópin yóò wà.
19 Hina bagade! Di da hanai galea, hina bagade sema amane hamoma, ‘Fa: sedai da dima bu hamedafa misunu’. Amo sema da Besia amola Midia ela sema dedei amo ganodini dedenanu, bu hamedafa afadenemu, di sia: ma. Amasea, Fa: sedai ea hina bagade uda sogebi, amo eno baligili noga: i udama ima.
“Nítorí náà, bí ó bá tọ́ lójú ọba, jẹ́ kí ó gbé àṣẹ ọba jáde, kí ó sì jẹ́ kí ó wà ní àkọsílẹ̀ pẹ̀lú òfin Persia àti Media, èyí tí kò le é parẹ́, pé kí Faṣti kí ó má ṣe wá síwájú ọba Ahaswerusi. Kí ọba sì fi oyè ayaba rẹ̀ fún ẹlòmíràn tí ó sàn jù ú lọ.
20 Dia fifi asi gala da bagadedafa. Dunu huluane amo ganodini esala, da dia sia: amo nababeba: le, uda huluane da ilia egoa (bagade gagui amola hame gagui defele), ilima nodone dawa: le, nabasu hou bu hamomu.”
Nígbà náà tí a bá kéde òfin tí ọba ṣe ká gbogbo ilẹ̀ ìjọba rẹ̀, gbogbo àwọn obìnrin ni yóò bọ̀wọ̀ fún ọkọ wọn, láti ọ̀dọ̀ ẹni tí ó kéré títí dé ọ̀dọ̀ ẹni ńlá.”
21 Hina bagade amola eagene ouligisu dunu da amo hou da noga: i dawa: beba: le, hina bagade da Mimiuga: ne ea sia: i defele hamoi.
Ìmọ̀ràn yìí sì tẹ́ ọba àti àwọn ìjòyè rẹ̀ lọ́rùn, nítorí náà ọba ṣe gẹ́gẹ́ bí Memukani ṣé sọ.
22 E da ea ouligisu fifi asi gala huluane ilima, e da ilila: sia: amola idisu amola dedesu hou defele, ilima sema amane dedene iagagai, “Egoa huluane da ilia sosogo fi ilima hinawane esalumu, amola eno da ilia sia: gua: mu da hamedei.”
Ó kọ̀wé ránṣẹ́ sí igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin ilẹ̀ ọba rẹ̀, ó kọ̀wé sí ìgbèríko kọ̀ọ̀kan ní ìlànà bí wọ́n ṣe ń kọ̀wé, ó kọ̀wé sí àwọn ènìyàn kọ̀ọ̀kan ní èdè wọn, Ó tẹnumọ́ ní èdè oníkálùkù pé kí olúkúlùkù ọkùnrin máa ṣàkóso ilé rẹ̀.

< Eseda 1 >