< Zephaniah 1 >

1 Sí olórí akọrin lórí ohun èlò orin olókùn mi. Ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Sefaniah ọmọ Kuṣi, ọmọ Gedaliah, ọmọ Amariah, ọmọ Hesekiah, ní ìgbà Josiah ọmọ Amoni ọba Juda.
Amonning oghli Yosiya Yehudagha padishah bolghan waqitlarda, Hezekiyaning chewrisi, Amariyaning ewrisi, Gedaliyaning newrisi, Kushining oghli Zefaniyagha yetken Perwerdigarning sözi: —
2 “Èmi yóò mú gbogbo nǹkan kúrò lórí ilẹ̀ náà pátápátá,” ni Olúwa wí.
Men yer yüzidin hemmini qurutuwétimen, — deydu Perwerdigar;
3 “Èmi yóò mú ènìyàn àti ẹranko kúrò; èmi yóò mú àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run kúrò, àti ẹja inú Òkun, àti ohun ìdìgbòlù pẹ̀lú àwọn ènìyàn búburú; èmi yóò ké ènìyàn kúrò lórí ilẹ̀ ayé,” ni Olúwa wí.
— Insan hem haywanni qurutuwétimen, Asmandiki uchar-qanatlar hem déngizdiki béliqlarni, Barliq putlikashanglarni rezil ademler bilen teng qurutuwétimen, Insaniyetni yer yüzidin üzüp tashlaymen, — deydu Perwerdigar.
4 “Èmi yóò na ọwọ́ mi sórí Juda àti sórí gbogbo àwọn ènìyàn tí ń gbé ní Jerusalẹmu. Èmi yóò sì ké kúrò níhìn-ín yìí ìyókù àwọn Baali, àti orúkọ àwọn abọ̀rìṣà pẹ̀lú àwọn àlùfáà abọ̀rìṣà,
— Shuning bilen Men Yehuda üstige, Barliq Yérusalémdikiler üstige qolumni sozimen; Mushu yerde «Baal»ning qalduqini, «Qémar»larning namini kahinlar bilen bille üzüp tashlaymen;
5 àti àwọn tí ń foríbalẹ̀ lórí òrùlé, àwọn tí ń sin ogun ọ̀run, àwọn tó ń foríbalẹ̀, tí wọ́n sì ń fi Olúwa búra, tí wọ́n sì ń fi Moleki búra.
Shundaqla ögzide turup asmandiki jisimlargha bash uridighanlarni, Perwerdigargha bash urup, shundaqla Uning nami bilen qesem qilip turup, «Malkam»ning nami bilenmu qesem qilidighanlarni,
6 Àwọn tí ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ Olúwa; àti àwọn tí kò tí wá Olúwa, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sì béèrè rẹ̀.”
Perwerdigardin tezgenlerni, Perwerdigarni izdimeydighan yaki Uningdin yol sorimighanlarnimu üzüp tashlaymen.
7 Ẹ dákẹ́ jẹ́ẹ́ níwájú Olúwa Olódùmarè, nítorí tí ọjọ́ Olúwa kù sí dẹ̀dẹ̀. Olúwa ti pèsè ẹbọ kan sílẹ̀, ó sì ti ya àwọn alápèjẹ rẹ̀ sí mímọ́.
Reb Perwerdigarning huzuri aldida süküt qilinglar; Chünki Perwerdigarning küni yéqindur; Chünki Perwerdigar qurbanliqni teyyarlidi, U méhmanlarni «taharet qildurup» halal qildi;
8 “Ní ọjọ́ ẹbọ Olúwa, Èmi yóò bẹ àwọn olórí wò, àti àwọn ọmọ ọba ọkùnrin, pẹ̀lú gbogbo àwọn tí ó wọ àjèjì aṣọ.
Perwerdigarning qurbanliqining künide shundaq boliduki, Men emirlerni, padishahlarning oghullirini we yat ellerning kiyimlirini kiyiwalghanlarning hemmisini jazalaymen;
9 Ní ọjọ́ náà, èmi yóò fi ìyà jẹ gbogbo àwọn tí ó yẹra láti rìn lórí ìloro ẹnu-ọ̀nà, tí wọ́n sì kún tẹmpili àwọn ọlọ́run wọn pẹ̀lú ìwà ipá àti ẹ̀tàn.
Shu küni Men bosughidin dessimey atlaydighanlarni, Yeni zulum-zorawanliq hem aldamchiliqqa tayinip, xojayinlirining öylirini tolduridighanlarni jazalaymen.
10 “Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí, “Ohùn ẹkún yóò wà láti ìhà ibodè ẹja, híhu láti ìhà kejì wá àti ariwo ńlá láti òkè kékeré wá.
Shu künide, — deydu Perwerdigar, «Béliq derwazisi»din «Waydad», «Ikkinchi mehelle»din hörkireshler, Döng-égizliklerdin ghayet zor «gum-gum» qilip weyran qilin’ghan awazlar anglinidu.
11 Ẹ hu, ẹ̀yin tí ń gbé ní agbègbè ọjà, gbogbo àwọn oníṣòwò rẹ̀ ni a ó mú kúrò, gbogbo àwọn ẹni tí ó ń ra fàdákà ni a ó sì parun.
«Hörkirenglar, i «Oymanliq mehellisi»dikiler; Chünki «sodiger xelq»ning hemmisi qilichlandi, Kümüsh bilen chingdalghanlar qirildi!»
12 Ní àkókò wọ̀n-ọn-nì, èmi yóò wá Jerusalẹmu kiri pẹ̀lú fìtílà, èmi ó sì fi ìyà jẹ àwọn tí kò ní ìtẹ́lọ́rùn, tí wọn sì dàbí àwọn ènìyàn tí ó sinmi sínú gẹ̀dẹ̀gẹ́dẹ̀ wọn, àwọn tí wọn sì ń wí ní ọkàn wọn pé, ‘Olúwa kì yóò ṣe nǹkan kan tí ó jẹ́ rere tàbí tí ó jẹ́ búburú.’
— We shu chaghda shundaq boliduki, Men Yérusalémni chiraghlar bilen axturimen, Arzangliri üstide tin’ghan sharabtek turghan endishisiz ademlerni, Yeni könglide: «Perwerdigar héch yaxshiliqni qilmaydu, yamanliqnimu qilmaydu» dégenlerni jazalaymen.
13 Nítorí náà, ọrọ̀ wọn yóò di ìkógun, àti ilé wọn yóò sì run. Àwọn yóò sì kọ́ ilé pẹ̀lú, ṣùgbọ́n wọn kì yóò gbé nínú ilé náà, wọn yóò gbin ọgbà àjàrà, ṣùgbọ́n wọn kì yóò mu ọtí wáìnì láti inú rẹ̀.”
Emdi bayliqliri olja, Öyliri berbat bolidu; Ular öylerni salghini bilen, Ularda turmaydu; Üzümzarlarni berpa qilghini bilen, Ularning sharabini ichmeydu.
14 “Ọjọ́ ńlá Olúwa kù sí dẹ̀dẹ̀, ó kù sí dẹ̀dẹ̀ ó sì ń yára bọ̀ kánkán. Ẹ tẹ́tí sílẹ̀, ohùn ẹkún àwọn alágbára; ní ọjọ́ Olúwa yóò korò púpọ̀,
Perwerdigarning ulugh küni yéqindur; Berheq yéqindur, intayin téz yétip kélidu; Angla, Perwerdigarning künining sadasi! Yétip kelgende palwanmu elemlik warqiraydu.
15 ọjọ́ náà yóò jẹ́ ọjọ́ ìbínú, ọjọ́ ìrora àti ìpọ́njú, ọjọ́ òfò àti idà ọjọ́ ìdahoro ọjọ́ òkùnkùn àti ìtẹ̀ba, ọjọ́ kurukuru àti òkùnkùn biribiri,
Shu küni qehr élip kélidighan bir kün, Külpetlik hem derd-elemlik bir kün, Weyranchiliq hem berbatliq chüshidighan bir kün, Zulmetlik hem sürlük bir kün, Bulutlar hem qap-qarangghuluq bilen qaplan’ghan bir kün,
16 ọjọ́ ìpè àti ìpè ogun sí àwọn ìlú olódi àti sí àwọn ilé ìṣọ́ gíga.
Istihkamlashqan sheherlerge, sépilning égiz poteylirige hujum qilidighan, Kanay chélinidighan, agah signali kötürülidighan bir kün bolidu.
17 “Èmi yóò sì mú ìpọ́njú wá sórí ènìyàn, wọn yóò sì máa rìn gẹ́gẹ́ bí afọ́jú, nítorí àwọn ti dẹ́ṣẹ̀ sí Olúwa. Ẹ̀jẹ̀ wọn ni a ó sì tú jáde bí eruku àti ẹran-ara wọn bí ìgbẹ́.
Men ademler üstige külpetlerni chüshürimen, — Ular qarighulardek yüridu; Chünki ular Perwerdigargha qarshi gunah qildi; Ularning qanliri topa-changdek, Ularning üchey-qérinliri poqtek tökülidu;
18 Bẹ́ẹ̀ ni fàdákà tàbí wúrà wọn kì yóò sì le gbà wọ́n là ní ọjọ́ ìbínú Olúwa.” Ṣùgbọ́n gbogbo ayé ni a ó fi iná ìjowú rẹ̀ parun, nítorí òun yóò fi ìyára fi òpin sí gbogbo àwọn tí ń gbé ní ilẹ̀ ayé.
Perwerdigarning qehri chüshken künide altun-kümüshliri ularni qutquzalmaydu; Belki pütkül jahan Uning ghezep oti teripidin yewétilidu; Chünki U barliq yer yüzidikilerning üstige mutleq bir halaket, dehshetlik bir halaket chüshüridu.

< Zephaniah 1 >