< Zechariah 9 >

1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀. Ọ̀rọ̀ Olúwa kọjú ìjà sí Hadiraki, Damasku ni yóò sì jẹ́ ibi ìsinmi rẹ̀; nítorí ojú Olúwa ń bẹ lára ènìyàn, àti lára gbogbo ẹ̀yà Israẹli.
Breme rijeèi Gospodnje zemlji Adrahu i Damasku, gdje æe poèinuti, jer je Gospodnje oko na ljudima i na svijem plemenima Izrailjevijem.
2 Àti Hamati pẹ̀lú yóò ṣe ààlà rẹ̀ Tire àti Sidoni bí o tilẹ̀ ṣe ọlọ́gbọ́n gidigidi.
I Emat æe zahvatiti, i Tir i Sidon, ako i jesu veoma mudri,
3 Tire sì mọ odi líle fún ara rẹ̀, ó sì kó fàdákà jọ bí eruku, àti wúrà dáradára bí ẹrẹ̀ ìgboro.
I Tir sagradi sebi grad, i sabra srebra kao praha, i zlata kao kala po putu.
4 Ṣùgbọ́n, Olúwa yóò kó gbogbo ohun ìní rẹ̀ lọ, yóò sì pa agbára rẹ̀ run ní ojú Òkun, a ó sì fi iná jó o run.
Gle, Gospod æe ga otjerati, i vræi æe u more silu njegovu, i on æe ognjem izgorjeti.
5 Aṣkeloni yóò rí í, yóò sì bẹ̀rù; Gasa pẹ̀lú yóò rí í, yóò sì káàánú gidigidi, àti Ekroni: nítorí tí ìrètí rẹ̀ yóò ṣákì í. Gasa yóò pàdánù ọba rẹ̀, Aṣkeloni yóò sì di ahoro.
Askalon æe vidjeti i uplašiæe se, i Gaza æe se vrlo uzmuèiti, i Akaron, što ga osramoti nadanje njegovo, i poginuæe car u Gazi; i Askalon se neæe naseliti.
6 Ọmọ àlè yóò sì gbé inú Aṣdodu, Èmi yóò sì gé ìgbéraga àwọn Filistini kúrò.
I u Azotu æe sjedjeti tuðin, i ponos æu Filistejski zatrti.
7 Èmi yóò sì mu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ kúrò ni ẹnu rẹ̀, àti àwọn ohun èèwọ̀ kúrò láàrín eyín rẹ̀: ṣùgbọ́n àwọn tó ṣẹ́kù yóò jẹ́ tí Ọlọ́run wa, wọn yóò sì jẹ baálẹ̀ ní Juda, àti Ekroni ni yóò rí bí Jebusi.
I ukloniæu krv njihovu od usta njihovijeh, i gadove njihove iz zuba njihovijeh, i ko ostane biæe i on Boga našega, i biæe kao poglavar u Judi, a Akaron kao Jevusejac.
8 Èmi yóò sì dó yí ilẹ̀ mi ká nítorí ogun àwọn tí wọ́n ń wá ohun tí wọn yóò bàjẹ́ kiri, kò sí aninilára tí yóò bori wọn mọ́: nítorí ni ìsinsin yìí ni mo fi ojú ṣọ́ wọn.
I postaviæu oko kod doma svojega suprot vojsci, suprot onima koji odlaze i dolaze, i nastojnik neæe više prolaziti kroz njih, jer sada pogledah svojim oèima.
9 Kún fún ayọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Sioni, hó ìhó ayọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Jerusalẹmu. Wò ó, ọba rẹ ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ: òdodo ni òun, ó sì ní ìgbàlà; ó ní ìrẹ̀lẹ̀, ó sì ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àní ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
Raduj se mnogo, kæeri Sionska, podvikuj, kæeri Jerusalimska; evo, car tvoj ide k tebi, pravedan je i spasava, krotak i jaše na magarcu, i na magaretu, mladetu magarièinu.
10 Èmi ó sì gbé kẹ̀kẹ́ kúrò ni Efraimu, àti ẹṣin ogun kúrò ni Jerusalẹmu, a ó sì ṣẹ́ ọrun ogun. Òun yóò sì kéde àlàáfíà sí àwọn kèfèrí. Ìjọba rẹ̀ yóò sì gbilẹ̀ láti Òkun dé Òkun, àti láti odò títí de òpin ayé.
Jer æu istrijebiti iz Jefrema kola i iz Jerusalima konje; i istrijebiæe se luk ubojiti; i on æe kazivati mir narodima, i vlast æe mu biti od mora do mora i od rijeke do krajeva zemaljskih.
11 Ní tìrẹ, nítorí ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú mi pẹ̀lú rẹ, Èmi ó dá àwọn ìgbèkùn rẹ̀ sílẹ̀ kúrò nínú ọ̀gbun.
A ti, za krv zavjeta tvojega pustih sužnje tvoje iz jame, gdje nema vode.
12 Ẹ padà sínú odi agbára yín, ẹ̀yin òǹdè ti o ni ìrètí: àní lónìí yìí èmi sọ pé, èmi o san án fún ọ ni ìlọ́po méjì.
Vratite se ka gradu, sužnji, koji se nadate, još ti i danas javljam da æu ti platiti dvojinom.
13 Èmi ó fa Juda le bí mo ṣe fa ọrun mi le, mo sì fi Efraimu kún un, Èmi yóò gbé àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin dìde, ìwọ Sioni, sí àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ìwọ Giriki, mo ṣe ọ́ bí idà alágbára.
Jer zapeh sebi Judu kao luk, i napunih Jefrema, i podigoh sinove tvoje, Sione, na sinove tvoje, Javane, i uèinih te da si kao maè junaèki.
14 Olúwa yóò sì fi ara hàn ní orí wọn; ọfà rẹ̀ yóò sì jáde lọ bí mọ̀nàmọ́ná. Olúwa Olódùmarè yóò sì fọn ìpè, Òun yóò sì lọ nínú atẹ́gùn ìjì gúúsù.
I Gospod æe se pokazati nad njima, i strijela æe njegova izaæi kao munja, i Gospod æe Gospod zatrubiti u trubu i poæi æe s vihorima južnijem.
15 Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò dáàbò bò wọ́n; wọn ó sì jẹ ni run, wọn ó sì tẹ òkúta kànnàkànnà mọ́lẹ̀; wọn ó sì mu ẹ̀jẹ̀ wọn bí wáìnì, wọn ó sì kún bí ọpọ́n, wọn ó sì rin ṣinṣin bí àwọn igun pẹpẹ.
Gospod nad vojskama zaklanjaæe ih, i oni æe jesti pogazivši kamenje iz praæe, i piæe podvikujuæi kao od vina, i biæe puni kao èaša, kao uglovi od oltara.
16 Olúwa Ọlọ́run wọn yóò sì gbà wọ́n là ni ọjọ́ náà bí agbo ènìyàn rẹ̀: nítorí wọn ó dàbí àwọn òkúta adé, tí a gbé sókè bí àmì lórí ilẹ̀ rẹ̀.
I Gospod Bog njihov izbaviæe ih u taj dan kao stado svojega naroda, jer æe se kamenje u vijencu podignuti u zemlji njegovoj.
17 Nítorí oore rẹ̀ tí tóbi tó, ẹwà rẹ̀ sì tí pọ̀! Ọkà yóò mú ọ̀dọ́mọkùnrin dárayá, àti ọtí wáìnì tuntun yóò mú àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin ṣe bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú.
Jer koliko æe biti dobro njegovo i kolika ljepota njegova! od žita æe rasti momci a od slatkoga vina djevojke.

< Zechariah 9 >