< Zechariah 9 >

1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀. Ọ̀rọ̀ Olúwa kọjú ìjà sí Hadiraki, Damasku ni yóò sì jẹ́ ibi ìsinmi rẹ̀; nítorí ojú Olúwa ń bẹ lára ènìyàn, àti lára gbogbo ẹ̀yà Israẹli.
Angraeng lokcaekhaih Hadrak hoi Damaska vangpui nuiah krah tih: Angraeng mah kaminawk hoi Israel acaengnawk to khet.
2 Àti Hamati pẹ̀lú yóò ṣe ààlà rẹ̀ Tire àti Sidoni bí o tilẹ̀ ṣe ọlọ́gbọ́n gidigidi.
Lokcaekhaih loe a taengah kaom Hamath vangpui nuiah krah tih, palungha kami ah kaom, Tura hoi Sidon nuiah doeh krah tih.
3 Tire sì mọ odi líle fún ara rẹ̀, ó sì kó fàdákà jọ bí eruku, àti wúrà dáradára bí ẹrẹ̀ ìgboro.
Tura loe misa buephaih kacak im to sak, sum kanglung to maiphu baktih, sui to loklam ih tangkrok baktiah patungh.
4 Ṣùgbọ́n, Olúwa yóò kó gbogbo ohun ìní rẹ̀ lọ, yóò sì pa agbára rẹ̀ run ní ojú Òkun, a ó sì fi iná jó o run.
Khenah, Angraeng mah anih to va ving ueloe, a thacakhaih to tuipui thungah amrosak tih; anih loe hmai mah kang tih.
5 Aṣkeloni yóò rí í, yóò sì bẹ̀rù; Gasa pẹ̀lú yóò rí í, yóò sì káàánú gidigidi, àti Ekroni: nítorí tí ìrètí rẹ̀ yóò ṣákì í. Gasa yóò pàdánù ọba rẹ̀, Aṣkeloni yóò sì di ahoro.
Ashkelon vangpui mah hnuk naah, zii tih; Gaza mah doeh hnu ueloe, paroeai palungsae tih; Ekron ih oephaih doeh azat thok hmuen ah angcoeng ving tih; Gaza siangpahrang to dueh tih, Ashkelon ah kami om mak ai boeh.
6 Ọmọ àlè yóò sì gbé inú Aṣdodu, Èmi yóò sì gé ìgbéraga àwọn Filistini kúrò.
Acaeng kangbaeh kaminawk loe Ashdod vangpui ah om o tih, Philistinnawk amoekhaih to kam rosak han.
7 Èmi yóò sì mu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ kúrò ni ẹnu rẹ̀, àti àwọn ohun èèwọ̀ kúrò láàrín eyín rẹ̀: ṣùgbọ́n àwọn tó ṣẹ́kù yóò jẹ́ tí Ọlọ́run wa, wọn yóò sì jẹ baálẹ̀ ní Juda, àti Ekroni ni yóò rí bí Jebusi.
Nihcae mah athii kaom moi to caa o mak ai ueloe, panuet thok caaknaek doeh caa o mak ai boeh; toe kanghmat kami loe aicae Sithaw hanah qawk ah om tih, anih loe Judah prae zaehoikung ah om ueloe, Ekron vangpui loe Jebus kami maeto ah om tih.
8 Èmi yóò sì dó yí ilẹ̀ mi ká nítorí ogun àwọn tí wọ́n ń wá ohun tí wọn yóò bàjẹ́ kiri, kò sí aninilára tí yóò bori wọn mọ́: nítorí ni ìsinsin yìí ni mo fi ojú ṣọ́ wọn.
Toe misatuk han caeh moe, amlaem kaminawk pongah, kaimah ih im to ka toep han: mi mah doeh kai ih kaminawk to pacaekthlaek let mak ai boeh. Kaom hmuen to mik hoi ka hnuk boeh.
9 Kún fún ayọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Sioni, hó ìhó ayọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Jerusalẹmu. Wò ó, ọba rẹ ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ: òdodo ni òun, ó sì ní ìgbàlà; ó ní ìrẹ̀lẹ̀, ó sì ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àní ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
Aw Zion canu, anghoe parai ah; Jerusalem canu hang ah: khenah, Na siangpahrang loe nang khaeah angzoh: anih loe toeng moe, pahlonghaih a tawnh; poek pahnaemhaih hoiah laa hrang nuiah angthueng, saning kanawk laa hrang nuiah angthueng hoiah angzoh.
10 Èmi ó sì gbé kẹ̀kẹ́ kúrò ni Efraimu, àti ẹṣin ogun kúrò ni Jerusalẹmu, a ó sì ṣẹ́ ọrun ogun. Òun yóò sì kéde àlàáfíà sí àwọn kèfèrí. Ìjọba rẹ̀ yóò sì gbilẹ̀ láti Òkun dé Òkun, àti láti odò títí de òpin ayé.
Ephraim khae ih hrang lakok to ka lak moe, Jerusalem khae ih misatukhaih hrang to ka lak pae han, misatukhaih kalii to ka khaeh pae han: anih mah Sithaw panoek ai kaminawk khaeah monghaih lok to thui pae tih: anih ukhaih loe tuipui hae bang hoi ho bang khoek to, vapui hoi long boeng khoek to kawk tih.
11 Ní tìrẹ, nítorí ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú mi pẹ̀lú rẹ, Èmi ó dá àwọn ìgbèkùn rẹ̀ sílẹ̀ kúrò nínú ọ̀gbun.
Athii hoi sak ih lokmaihaih loe nangcae han doeh oh toeng pongah, thongim krah kaminawk to tui om ai tangqom thung hoiah ka loisak han.
12 Ẹ padà sínú odi agbára yín, ẹ̀yin òǹdè ti o ni ìrètí: àní lónìí yìí èmi sọ pé, èmi o san án fún ọ ni ìlọ́po méjì.
Thongim krah kaminawk, amlaem oh, oephaih kang paek o; nangcae han alet hnetto tangqum kang paek o han, tiah vaihi kang thuih o boeh.
13 Èmi ó fa Juda le bí mo ṣe fa ọrun mi le, mo sì fi Efraimu kún un, Èmi yóò gbé àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin dìde, ìwọ Sioni, sí àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ìwọ Giriki, mo ṣe ọ́ bí idà alágbára.
Judah to kalii avak baktiah ka vak moe, Ephraim ih kalii to ka koisak han, Aw Zion na capanawk to ka pathawk han, Aw Grik na capanawk to misa ah ka suek moe, thacak kami ih sumsen baktiah kang coengsak han.
14 Olúwa yóò sì fi ara hàn ní orí wọn; ọfà rẹ̀ yóò sì jáde lọ bí mọ̀nàmọ́ná. Olúwa Olódùmarè yóò sì fọn ìpè, Òun yóò sì lọ nínú atẹ́gùn ìjì gúúsù.
Nihcae nuiah Angraeng amtueng tih, anih ih kalii loe ni aengh baktiah ampha tih: Angraeng Sithaw mah mongkah to ueng ueloe, aloih bang ih takhi hoiah caeh tih.
15 Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò dáàbò bò wọ́n; wọn ó sì jẹ ni run, wọn ó sì tẹ òkúta kànnàkànnà mọ́lẹ̀; wọn ó sì mu ẹ̀jẹ̀ wọn bí wáìnì, wọn ó sì kún bí ọpọ́n, wọn ó sì rin ṣinṣin bí àwọn igun pẹpẹ.
Misatuh kaminawk ih Angraeng mah angmah ih kaminawk to pakaa tih; nihcae to amrosak ueloe, zai ih lawkthluemnawk doeh pazawk tih: nihcae loe misurtui nae kaminawk baktiah hang o tih; nihcae loe hmuenpaekhaih sak nathuem ih kakoi mong sabae baktih, im takii ih hmaicam baktiah om o tih.
16 Olúwa Ọlọ́run wọn yóò sì gbà wọ́n là ni ọjọ́ náà bí agbo ènìyàn rẹ̀: nítorí wọn ó dàbí àwọn òkúta adé, tí a gbé sókè bí àmì lórí ilẹ̀ rẹ̀.
To na niah loe angmacae ih Angraeng Sithaw mah angmah ih tuucaanawk baktiah nihcae to pahlong tih: nihcae loe Angraeng lumuek pong ih atho kaom thlung baktiah om o ueloe, pazawkhaih kahni baktiah a prae thungah aang tih.
17 Nítorí oore rẹ̀ tí tóbi tó, ẹwà rẹ̀ sì tí pọ̀! Ọkà yóò mú ọ̀dọ́mọkùnrin dárayá, àti ọtí wáìnì tuntun yóò mú àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin ṣe bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú.
Nihcae hoihhaih loe kawkruk maw len, a krang hoihhaih doeh kawkrukmaw len tih! Thendoengnawk loe laikok ih cang baktiah qoeng o ueloe, takha thung ih misurkung baktiah qoeng o tih.

< Zechariah 9 >