< Zechariah 8 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun si tún tọ́ mí wá.
Misatuh kaminawk ih Angraeng ih lok kai khaeah angzoh let,
2 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “Owú ńlá ńlá ni mo jẹ fún Sioni, pẹ̀lú ìbínú ńlá ńlá ni mo fi jowú fún un.”
misatuh kaminawk ih Angraeng mah, Zion nuiah paroeai uthaih ka tawnh, anih nuiah hmai kanung parai palungphuihaih ka tawnh, tiah thuih.
3 Báyìí ni Olúwa wí, “Mo yípadà sí Sioni èmi ó sì gbé àárín Jerusalẹmu. Nígbà náà ni a ó sì pé Jerusalẹmu ni ìlú ńlá òtítọ́; àti òkè ńlá Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ni a ó pè ní òkè ńlá mímọ́.”
Angraeng mah, Zion khaeah kam laem let moe, Jerusalem thungah ka oh han: Jerusalem loe Loktang Vangpui, tiah kawk o ueloe, misatuh kaminawk ih Angraeng ih Mae loe, Kaciim Mae, tiah kawk o tih, tiah thuih.
4 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “Arúgbó ọkùnrin, àti arúgbó obìnrin, yóò gbé ìgboro Jerusalẹmu, àti olúkúlùkù pẹ̀lú ọ̀pá ni ọwọ́ rẹ̀ fún ogbó.
Misatuh kaminawk ih Angraeng mah, Nongpata mitong hoi nongpa mitongnawk loe Jerusalem ih loklamnawk ah anghnu o ueloe, saning coeh o parai boeh pongah, ban ah cunghet to sin o boih tih.
5 Ìgboro ìlú yóò sì kún fún ọmọdékùnrin, àti ọmọdébìnrin, tí ń ṣiré ní ìta wọn.”
Vangpui thung ih loklamnawk loe nawkta nongpa hoi nongpatanawk amhaihaih hoiah koi tih, tiah thuih.
6 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Bí ó bá ṣe ìyanu ní ojú ìyókù àwọn ènìyàn yìí ni ọjọ́ wọ̀nyí, ǹjẹ́ ó ha lè jẹ́ ìyanu ni ojú mi bí?” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Misatuh kaminawk ih Angraeng mah, To na niah loe haeah kanghmat kaminawk hanah dawnrai hmuen ah om tih, toe kai han loe dawnrai hmuen ah om tih maw? tiah misatuh kaminawk ih Angraeng mah thuih.
7 Báyìí ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Kíyèsi i, èmi ó gba àwọn ènìyàn mi kúrò ni ilẹ̀ ìlà-oòrùn, àti kúrò ni ilẹ̀ ìwọ̀-oòrùn.
Misatuh kaminawk ih Angraeng mah, Khenah, ni angyae hoi ni duem prae bangah kaom, kaimah ih kaminawk to ka pahlong han.
8 Èmi ó sì mú wọn padà wá, wọn ó sì máa gbé àárín Jerusalẹmu. Wọn ó sì jẹ́ ènìyàn mi, èmi ó sì jẹ́ Ọlọ́run wọn, ní òtítọ́, àti ní òdodo.”
Jerusalem ah oh hanah nihcae to ka hoih han: nihcae loe kai ih kami ah om o ueloe, kai loe loktang hoi toenghaih bangah nihcae ih Sithaw ah ka oh han, tiah thuih.
9 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Jẹ́ kí ọwọ́ yín le ẹ̀yin ti ń gbọ́ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí ní ọjọ́ wọ̀nyí ni ẹnu àwọn wòlíì tí ó wà ni ọjọ́ tí a fi ìpìlẹ̀ ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun lélẹ̀, jẹ́ ki ọwọ́ rẹ̀ le kí a bá lè kọ́ tẹmpili.
Misatuh kaminawk ih Angraeng mah, Misatuh kaminawk ih Angraeng ih im sak na niah kaom tahmaanawk ih lok kathaih nangcae mah, tempul to na sak o thai hanah, na ban thacak o sak ah.
10 Nítorí pé, ṣáájú ọjọ́ wọ̀nyí, owó ọ̀yà ènìyàn kò tó nǹkan, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀yà ẹran pẹ̀lú, bẹ́ẹ̀ ni kò sí àlàáfíà fún ẹni ń jáde lọ, tàbí ẹni ti ń wọlé bọ, nítorí ìpọ́njú náà: nítorí mo dojú gbogbo ènìyàn, olúkúlùkù kọ aládùúgbò rẹ̀.
Hae tiah om ai nathuem ah loe kami hoi moi hanah toksakhaih atho to om ai; kaminawk boih hoi a taeng ih kaminawk maeto hoi maeto misa ah kang coengsak pongah, pacaekthlaekhaih to oh moe, tacawt kami hoi akun kaminawk hanah monghaih om ai.
11 Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí èmi kì yóò ṣè sí ìyókù àwọn ènìyàn yìí gẹ́gẹ́ bí tí ìgbà àtijọ́,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Toe vaihi loe kanghmat kaminawk to canghnii ih kaminawk baktiah ka sah mak ai, tiah misatuh kaminawk ih Angraeng mah thuih.
12 “Nítorí irúgbìn yóò gbilẹ̀, àjàrà yóò ṣo èso rẹ̀, ilẹ̀ yóò sì hu ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan rẹ̀ jáde, àwọn ọ̀run yóò sì mu ìrì wọn wá; èmi ó sì mu kí èyí jẹ ogún ìní àwọn ìyókù ènìyàn yìí ni gbogbo nǹkan wọ̀nyí.
Atii loe kahoih ah amprawk ueloe, misur doeh athai tih; long mah caaknaek to tacawtsak ueloe, vannawk mah dantui to krahsak tih: haeah kanghmat kaminawk hanah hae hmuennawk boih qawk ah ka toepsak han.
13 Yóò sì ṣe, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin tí jẹ́ ègún láàrín àwọn kèfèrí, ẹ̀yin ilé Juda, àti ilé Israẹli, bẹ́ẹ̀ ni èmi ó gbà yín sílẹ̀; ẹ̀yin o sì jẹ́ ìbùkún, ẹ má bẹ̀rù, ṣùgbọ́n jẹ́ ki ọwọ́ yín le.”
Nangcae loe Sithaw panoek ai kaminawk salakah tangoenghaih hnu kami ah na oh o baktih toengah, Aw Judah hoi Israel imthung takohnawk, nangcae to kang pahlong han, to naah nangcae loe tahamhoih kami ah na om o tih: zii hmah, na ban thacak o sak ah, tiah a naa.
14 Nítorí báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Gẹ́gẹ́ bí mo ti rò láti ṣe yín níbi nígbà tí àwọn baba yín mú mi bínú,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, tí èmi kò sì ronúpìwàdà.
Misatuh kaminawk ih Angraeng mah, Nangcae ampanawk mah kai palung ang phui o sak naah, nangcae to dan ka paek han, tiah ka thuih ih lok to ka zuk let ai;
15 “Bẹ́ẹ̀ ni èmi sì ti ro ọjọ́ wọ̀nyí láti ṣe rere fún Jerusalẹmu, àti fún ilé Juda: ẹ má bẹ̀rù.
vaihni loe Jerusalem hoi Judah imthung takoh ah kahoih hmuen sak han kam sak boeh; zii o hmah.
16 Wọ̀nyí ni nǹkan tí ẹ̀yin ó ṣe: ki olúkúlùkù yín kí ó máa ba ọmọnìkejì rẹ̀ sọ òtítọ́; ṣe ìdájọ́ tòótọ́ àti àlàáfíà ní àwọn ibodè yín.
Hae baktih hmuennawk hae na sak o han oh; kami boih mah angmah ih imtaeng kaminawk khaeah loktang lok to thui oh; lokcaek naah loktang lok, toenghaih lok, monghaih hoiah lok to takhroek oh:
17 Ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnìkan ro ibi ni ọkàn rẹ̀ sí ẹnìkejì rẹ̀; ẹ má fẹ́ ìbúra èké; nítorí gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni mo kórìíra,” ni Olúwa wí.
na imtaeng kami nuiah kahoih ai hmuen to poek o hmah; amsoem ai lokkamhaih to koeh o hmah: hae tiah sak ih hmuennawk loe ka hnukma, tiah Angraeng mah thuih.
18 Ọ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun sì tọ mi wá wí pé.
Misatuh kaminawk ih Angraeng ih lok kai khaeah angzoh let bae,
19 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé: “Àwẹ̀ oṣù kẹrin, karùn-ún, keje, àti tí ẹ̀kẹwàá, yóò jẹ́ ayọ̀ àti dídùn inú, àti àpéjọ àríyá fún ilé Juda; nítorí náà, ẹ fẹ́ òtítọ́ àti àlàáfíà.”
misatuh kaminawk ih Angraeng mah, Khrah palito, khrah pangato, khrah sarihto hoi khrah hato, buhzahhaihnawk loe Judah imthung takoh han oephaih, anghoehaih hoi nawmhaih poih ah om tih; to pongah loktang hoi angdaehhaih to palung oh, tiah thuih.
20 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Àwọn ènìyàn yóò sá à tún wa, àti ẹni tí yóò gbe ìlú ńlá púpọ̀.
Misatuh kaminawk ih Angraeng mah, Ahmuen kruekah kaom vangpui ih kaminawk to angzo o tih:
21 Àwọn ẹni tí ń gbé ìlú ńlá kan yóò lọ sí òmíràn, wí pé, ‘Ẹ jẹ́ kí a yára lọ gbàdúrà kí a sì wá ojúrere Olúwa, àti láti wá Olúwa àwọn ọmọ-ogun. Èmi pẹ̀lú yóò sì lọ.’
vangpui maeto thung kaom kaminawk loe kalah vangpui bangah caeh o ueloe, Misatuh kaminawk ih Angraeng to pakrong o si, Angraeng hmaa ah lawkthuih han karangah caeh o si, kai doeh ka caeh toeng han, tiah thui o tih.
22 Nítòótọ́, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn àti àwọn alágbára orílẹ̀-èdè yóò wá láti wá Olúwa àwọn ọmọ-ogun ní Jerusalẹmu; àti láti gbàdúrà, àti láti wá ojúrere Olúwa.”
Ue, pop parai kaminawk hoi thacak praenawk mah misatuh kaminawk ih Angraeng to pakrong moe, Angraeng hmaa ah lawkthuih hanah Jerusalem ah angzo o tih, tiah a thuih.
23 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Ní àwọn ọjọ́ wọ̀nyí ni ọkùnrin mẹ́wàá láti inú gbogbo èdè àti orílẹ̀-èdè yóò dìímú, àní yóò di etí aṣọ ẹni tí i ṣe Júù mú, wí pé, ‘Àwa yóò ba ọ lọ, nítorí àwa tí gbọ́ pé, Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ.’”
Misatuh kaminawk ih Angraeng mah, To na niah loe lok kalah apae praenawk thung ih kaminawk hato angzo o ueloe, Judah kami maeto ih kahni atom to patawn pae o caeng tih, nangcae khaeah Sithaw oh, tiah ka thaih o pongah, na hnukah kang zoh o toeng han, tiah thui o tih, tiah thuih.

< Zechariah 8 >