< Zechariah 8 >
1 Ọ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun si tún tọ́ mí wá.
Hina Gode Bagadedafa da amo sia: ne iasu, Segalaiama i,
2 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “Owú ńlá ńlá ni mo jẹ fún Sioni, pẹ̀lú ìbínú ńlá ńlá ni mo fi jowú fún un.”
“Na da Yelusaleme fidimusa: bagade dadawa: la. Bai Na da Yelusaleme fi dunuma bagade oso dogone asigisa. Na da Yelusaleme fi dunuma asigiba: le, Na da ilia ha lai dunu ilima bagadewane ougi gala.
3 Báyìí ni Olúwa wí, “Mo yípadà sí Sioni èmi ó sì gbé àárín Jerusalẹmu. Nígbà náà ni a ó sì pé Jerusalẹmu ni ìlú ńlá òtítọ́; àti òkè ńlá Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ni a ó pè ní òkè ńlá mímọ́.”
Na da Yelusaleme, Na hadigi moilai bai bagade fi ilima buhagili amogai esalumu. Amasea, ilia Yelusalemega Dafawanedafa Moilai bai bagade dio asulimu. Amola Gadodafa Hina Gode Bagadedafa Ea goumi, amoma ilia da Hadigidafa Goumi dio asulimu.
4 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “Arúgbó ọkùnrin, àti arúgbó obìnrin, yóò gbé ìgboro Jerusalẹmu, àti olúkúlùkù pẹ̀lú ọ̀pá ni ọwọ́ rẹ̀ fún ogbó.
Bu enowane, da: i hamoi dunu amola uda da bagadedafa da: i hamoi ba: le, ilia da galiamoga ili ahoabe da Yelusaleme gagoi ganodini esalebe ba: mu.
5 Ìgboro ìlú yóò sì kún fún ọmọdékùnrin, àti ọmọdébìnrin, tí ń ṣiré ní ìta wọn.”
Amola bu enowane, logoba: le da dunu mano amola uda mano bagohamedafa da hehedela lafia: lebe ba: mu.
6 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Bí ó bá ṣe ìyanu ní ojú ìyókù àwọn ènìyàn yìí ni ọjọ́ wọ̀nyí, ǹjẹ́ ó ha lè jẹ́ ìyanu ni ojú mi bí?” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Amo hou da Isala: ili fi dunu waha hame bogoi esalebe, ilia hamomu defele hame ba: mu. Be Na da amo hamomu defele gala.
7 Báyìí ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Kíyèsi i, èmi ó gba àwọn ènìyàn mi kúrò ni ilẹ̀ ìlà-oòrùn, àti kúrò ni ilẹ̀ ìwọ̀-oòrùn.
Na da Na fi dunu eno sogega mugululi oule asi, amo gaga: mu.
8 Èmi ó sì mú wọn padà wá, wọn ó sì máa gbé àárín Jerusalẹmu. Wọn ó sì jẹ́ ènìyàn mi, èmi ó sì jẹ́ Ọlọ́run wọn, ní òtítọ́, àti ní òdodo.”
Na da ili gusudili amola guma: dini amoga lale, bu Yelusaleme amoga esaloma: ne oule misunu. Ilia da Na fi dunu esalumu, amola Na da ilia Gode esalumu. Amola Na da mae fisili, moloidafawane ili ouligimu.
9 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Jẹ́ kí ọwọ́ yín le ẹ̀yin ti ń gbọ́ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí ní ọjọ́ wọ̀nyí ni ẹnu àwọn wòlíì tí ó wà ni ọjọ́ tí a fi ìpìlẹ̀ ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun lélẹ̀, jẹ́ ki ọwọ́ rẹ̀ le kí a bá lè kọ́ tẹmpili.
Mae beda: ma! Yelusaleme fi dunu da Na Debolo Diasu bai fa: lalu, balofede dunu da Na waha sia: i liligi dilima sia: i. Amola dilia da amo waha bu naba.
10 Nítorí pé, ṣáájú ọjọ́ wọ̀nyí, owó ọ̀yà ènìyàn kò tó nǹkan, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀yà ẹran pẹ̀lú, bẹ́ẹ̀ ni kò sí àlàáfíà fún ẹni ń jáde lọ, tàbí ẹni ti ń wọlé bọ, nítorí ìpọ́njú náà: nítorí mo dojú gbogbo ènìyàn, olúkúlùkù kọ aládùúgbò rẹ̀.
Amo eso hame doaga: iyawane, dunu da hame gaguiba: le, dunu o ohe hawa: hamomusa: bidi lamu da hamedei ba: i. Amola ha lai dunu bagohameba: le, gaga: su ba: mu da hamedei ba: i. Bai Na da dunu ili gobele gegema: ne hamonesi.
11 Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí èmi kì yóò ṣè sí ìyókù àwọn ènìyàn yìí gẹ́gẹ́ bí tí ìgbà àtijọ́,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Be Isala: ili fi dunu hame bogoi esalebe, ilima Na da wali hou hisu hamonana.
12 “Nítorí irúgbìn yóò gbilẹ̀, àjàrà yóò ṣo èso rẹ̀, ilẹ̀ yóò sì hu ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan rẹ̀ jáde, àwọn ọ̀run yóò sì mu ìrì wọn wá; èmi ó sì mu kí èyí jẹ ogún ìní àwọn ìyókù ènìyàn yìí ni gbogbo nǹkan wọ̀nyí.
Ilia da olofoiwane ilia ha: i manu sagamu. Waini efe da fage legemu, osoboga da ha: i manu heda: mu, amola gibu bagade da sa: imu. Na da amo hahawane dogolegele hou huluane Na fi dunu hame bogoi esalebe, ilima hamomu.
13 Yóò sì ṣe, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin tí jẹ́ ègún láàrín àwọn kèfèrí, ẹ̀yin ilé Juda, àti ilé Israẹli, bẹ́ẹ̀ ni èmi ó gbà yín sílẹ̀; ẹ̀yin o sì jẹ́ ìbùkún, ẹ má bẹ̀rù, ṣùgbọ́n jẹ́ ki ọwọ́ yín le.”
Yuda dunu amola Isala: ili dunu! Musa: ga fi dunu da eno enoia amane gagabusu aligima: ne ilegele sia: i, ‘Gugunufinisisu hou amo da Yuda amola Isala: ili fi ilima doaga: i da dilima doaga: ma: ne ninia da ilegesa.’ Be Na da dili gaga: mu. Amasea, amo ga fi dunu da eno enoia amane sia: mu, ‘Hahawane dogolegele hou amo da Yuda amola Isala: ili fi ilima doaga: i, amo defele dilima doaga: mu da defea.’ Amaiba: le, dilia dogo denesini, mae beda: ma!”
14 Nítorí báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Gẹ́gẹ́ bí mo ti rò láti ṣe yín níbi nígbà tí àwọn baba yín mú mi bínú,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, tí èmi kò sì ronúpìwàdà.
Hina Gode Bagadedafa da amane sia: sa, “Dilia aowalalia da Na ougima: ne hamobeba: le, Na da ili wadela: lesima: ne ilegei. Amola Na asigi dawa: su mae afadenene, dafawane amo ilegei hamoi dagoi.
15 “Bẹ́ẹ̀ ni èmi sì ti ro ọjọ́ wọ̀nyí láti ṣe rere fún Jerusalẹmu, àti fún ilé Juda: ẹ má bẹ̀rù.
Be wali Na da Yelusaleme fi amola Yuda fi ilima hahawane dogolegele ima: ne ilegelala. Amaiba: le, mae beda: ma!
16 Wọ̀nyí ni nǹkan tí ẹ̀yin ó ṣe: ki olúkúlùkù yín kí ó máa ba ọmọnìkejì rẹ̀ sọ òtítọ́; ṣe ìdájọ́ tòótọ́ àti àlàáfíà ní àwọn ibodè yín.
Dilia amo hou agoane hamoma; ‘Eno enoma dafawane sia: fawane sia: ma! Fofada: su diasu ganodini, moloidafa hou (hou amo da olofosu iaha) amo fawane hamoma.
17 Ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnìkan ro ibi ni ọkàn rẹ̀ sí ẹnìkejì rẹ̀; ẹ má fẹ́ ìbúra èké; nítorí gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni mo kórìíra,” ni Olúwa wí.
Dilia eno enoma se imunusa: mae ilegema. Dilia fofada: su ganodini, ilegele sia: sea, ogogosu sia: mae sia: ma. Na da ogogosu amola moloi hame hou amola gegene nimi dasu hou huluane bagade higasa.’”
18 Ọ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun sì tọ mi wá wí pé.
Hina Gode Bagadedafa da Segalaiama amane sia: ne i,
19 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé: “Àwẹ̀ oṣù kẹrin, karùn-ún, keje, àti tí ẹ̀kẹwàá, yóò jẹ́ ayọ̀ àti dídùn inú, àti àpéjọ àríyá fún ilé Juda; nítorí náà, ẹ fẹ́ òtítọ́ àti àlàáfíà.”
“Ha: i mae nawene gilisisu dilia da oubi biyadu amola bi amola fesu amola nabu amoga hamosa, amo Na da afadenene Yuda dunu ilia nodone hahawane lolo nasu bu hamomu. Dilia asigi hou, dafawane hou amola olofosu hou amo hanama!”
20 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Àwọn ènìyàn yóò sá à tún wa, àti ẹni tí yóò gbe ìlú ńlá púpọ̀.
Hina Gode Bagadedafa da amane sia: sa, “Eso da mana, amoga ga fi dunu amo da moilai bai bagade bagohame amoga esalebe da Yelusaleme moilai bai bagadega misunu.
21 Àwọn ẹni tí ń gbé ìlú ńlá kan yóò lọ sí òmíràn, wí pé, ‘Ẹ jẹ́ kí a yára lọ gbàdúrà kí a sì wá ojúrere Olúwa, àti láti wá Olúwa àwọn ọmọ-ogun. Èmi pẹ̀lú yóò sì lọ.’
Moilai bai bagade dunu eno da moilai bai bagade dunu enoma amane sia: mu, ‘Ninia da Hina Gode Bagadedafa Ema nodone sia: ne gadoma: ne amola Ea hahawane dogolegele fidisu hogole ba: ma: ne masunu. Nini ahoa: di! Misa!’
22 Nítòótọ́, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn àti àwọn alágbára orílẹ̀-èdè yóò wá láti wá Olúwa àwọn ọmọ-ogun ní Jerusalẹmu; àti láti gbàdúrà, àti láti wá ojúrere Olúwa.”
Fifi asi gala bagohame ilia dunu amola gasa bagade fifi asi gala fi dunu ilia da Hina Gode Bagadedafa Ema nodone sia: ne gadomusa: amola Ema Ea hahawane dogolegele fidisu edegema: ne, Yelusalemema misunu.
23 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Ní àwọn ọjọ́ wọ̀nyí ni ọkùnrin mẹ́wàá láti inú gbogbo èdè àti orílẹ̀-èdè yóò dìímú, àní yóò di etí aṣọ ẹni tí i ṣe Júù mú, wí pé, ‘Àwa yóò ba ọ lọ, nítorí àwa tí gbọ́ pé, Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ.’”
Amo esoha, ga fi dunu nabuane gala da Yu dunu afae amoma misini, ema amane sia: mu, ‘Ninia dima hobea misunu hou amo gilisili ba: mu hanai gala. Bai Gode da dili esala, amo sia: be ninia nabi dagoi.’”