< Zechariah 7 >

1 Ó sì ṣe ní ọdún kẹrin Dariusi ọba, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ́ Sekariah wá ni ọjọ́ kẹrin oṣù Kisleu tí ń ṣe oṣù kẹsànán.
and to be in/on/with year four to/for Darius [the] king to be word LORD to(wards) Zechariah in/on/with four to/for month [the] ninth in/on/with Chislev
2 Nígbà tí wọ́n ènìyàn Beteli rán Ṣareseri àti Regemmeleki, àti àwọn ènìyàn wọn sí ilé Ọlọ́run láti wá ojúrere Olúwa.
and to send: depart Bethel Bethel Sharezer Sharezer and Regem-melech Regem-melech and human his to/for to beg [obj] face of LORD
3 Àti láti bá àwọn àlùfáà tí ó wà ní ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun, àti àwọn wòlíì sọ̀rọ̀ wí pé, “Ṣé kí èmi ó sọkún ní oṣù karùn-ún kí èmi ya ara mi sọ́tọ̀, bí mo ti ń ṣe láti ọdún mélòó wọ̀nyí wá bí?”
to/for to say to(wards) [the] priest which to/for house: temple LORD Hosts and to(wards) [the] prophet to/for to say to weep in/on/with month [the] fifth to dedicate like/as as which to make: do this like/as what? year
4 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tọ̀ mí wá pé,
and to be word LORD Hosts to(wards) me to/for to say
5 “Sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, àti fún àwọn àlùfáà pé, ‘Nígbà tí ẹ̀yin gbààwẹ̀, tí ẹ sì ṣọ̀fọ̀ ní oṣù karùn-ún àti keje, àní fun àádọ́rin ọdún wọ̀nyí, ǹjẹ́ èmi ni ẹ̀yin ha ń gbààwẹ̀ yín fún?
to say to(wards) all people [the] land: country/planet and to(wards) [the] priest to/for to say for to fast and to mourn in/on/with fifth and in/on/with seventh and this seventy year to fast to fast me I
6 Nígbà tí ẹ sì jẹ, àti nígbà tí ẹ mu, fún ara yín kọ́ ni ẹ̀yin jẹ, àti fún ara yín kọ́ ni ẹ̀yin mú bí?
and for to eat and for to drink not you(m. p.) [the] to eat and you(m. p.) [the] to drink
7 Wọ̀nyí kọ́ ni ọ̀rọ̀ ti Olúwa ti kígbe láti ọ̀dọ̀ àwọn wòlíì ìṣáájú wá, nígbà tí a ń gbé Jerusalẹmu, tí ó sì wà ní àlàáfíà, pẹ̀lú àwọn ìlú rẹ̀ tí ó yí i káàkiri, nígbà tí a ń gbé gúúsù àti pẹ̀tẹ́lẹ̀.’”
not [obj] [the] word which to call: call out LORD in/on/with hand: by [the] prophet [the] first: previous in/on/with to be Jerusalem to dwell and at ease and city her around her and [the] Negeb and [the] Shephelah to dwell
8 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Sekariah wá, wí pé,
and to be word LORD to(wards) Zechariah to/for to say
9 “Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, ‘Ṣe ìdájọ́ òtítọ́, kí ẹ sì ṣe àánú àti ìyọ́nú olúkúlùkù sí arákùnrin rẹ̀.
thus to say LORD Hosts to/for to say justice: judgement truth: true to judge and kindness and compassion to make: do man: anyone with brother: compatriot his
10 Má sì ṣe ni opó lára tàbí aláìní baba, àlejò, tàbí tálákà; kí ẹnikẹ́ni nínú yín má ṣe gbèrò ibi ní ọkàn sí arákùnrin rẹ̀.’
and widow and orphan sojourner and afflicted not to oppress and distress: evil man: anyone brother: compatriot his not to devise: devise in/on/with heart your
11 “Ṣùgbọ́n wọ́n kọ̀ láti gbọ́, wọ́n sì gún èjìká, wọ́n sì pa ẹ̀yìn dà, wọ́n di etí wọn, kí wọn má ba à gbọ́.
and to refuse to/for to listen and to give: put shoulder to rebel and ear their to honor: dull from to hear: hear
12 Wọ́n sé ọkàn wọn bí òkúta líle, kí wọn má ba à gbọ́ òfin, àti ọ̀rọ̀ tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti fi ẹ̀mí rẹ̀ rán nípa ọwọ́ àwọn wòlíì ìṣáájú wá. Ìbínú ńlá sì dé láti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
and heart their to set: make thorn from to hear: hear [obj] [the] instruction and [obj] [the] word which to send: depart LORD Hosts in/on/with spirit his in/on/with hand: by [the] prophet [the] first: previous and to be wrath great: large from with LORD Hosts
13 “‘Ó sì ṣe, gẹ́gẹ́ bí ó ti kígbe, tí wọn kò sì fẹ́ gbọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n kígbe, tí èmi kò sì fẹ́ gbọ́,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
and to be like/as as which to call: call to and not to hear: hear so to call: call to and not to hear: hear to say LORD Hosts
14 ‘Mo sì fi ìjì tú wọn ká sí gbogbo orílẹ̀-èdè tí wọn kò mọ̀. Ilẹ̀ náà sì dahoro lẹ́yìn wọn, tí ẹnikẹ́ni kò là á kọjá tàbí kí ó padà bọ̀, wọ́n sì sọ ilẹ̀ ààyò náà dahoro.’”
and to rage them upon all [the] nation which not to know them and [the] land: country/planet be desolate: destroyed after them from to pass and from to return: repent and to set: make land: country/planet desire to/for horror: destroyed

< Zechariah 7 >