< Zechariah 7 >
1 Ó sì ṣe ní ọdún kẹrin Dariusi ọba, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ́ Sekariah wá ni ọjọ́ kẹrin oṣù Kisleu tí ń ṣe oṣù kẹsànán.
Darius siangpahrang uknae kum pali, thapa yung tako, Chislev hnin pali hnin nah Zekhariah koe BAWIPA e lawk ka tho e teh,
2 Nígbà tí wọ́n ènìyàn Beteli rán Ṣareseri àti Regemmeleki, àti àwọn ènìyàn wọn sí ilé Ọlọ́run láti wá ojúrere Olúwa.
BAWIPA e hmalah ratoum hanlah kum moikasaw sak e patetlah thapa yung panga navah, khuika teh bu hai han nama telah,
3 Àti láti bá àwọn àlùfáà tí ó wà ní ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun, àti àwọn wòlíì sọ̀rọ̀ wí pé, “Ṣé kí èmi ó sọkún ní oṣù karùn-ún kí èmi ya ara mi sọ́tọ̀, bí mo ti ń ṣe láti ọdún mélòó wọ̀nyí wá bí?”
Ransahu BAWIPA e im dawk kaawm e vaihma hoiyah profetnaw hah pacei hanelah, Sherezer, Regem Melek hoi ahnimae taminaw BAWIPA e im dawk a patoun awh.
4 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tọ̀ mí wá pé,
Ransahu BAWIPA e lawk teh Zekhariah koe a pha teh,
5 “Sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, àti fún àwọn àlùfáà pé, ‘Nígbà tí ẹ̀yin gbààwẹ̀, tí ẹ sì ṣọ̀fọ̀ ní oṣù karùn-ún àti keje, àní fun àádọ́rin ọdún wọ̀nyí, ǹjẹ́ èmi ni ẹ̀yin ha ń gbààwẹ̀ yín fún?
vaihmanaw hoi khocaramcanaw pueng hanelah na dei hane teh, a kum 70 touh thung, nangmanaw teh thapa ayung panga e hoi ayung sari e dawkvah bu na hai awh teh na khuika awh navah atangcalah kaie ka ngainae patetlah Kai koe bu na hai awh maw.
6 Nígbà tí ẹ sì jẹ, àti nígbà tí ẹ mu, fún ara yín kọ́ ni ẹ̀yin jẹ, àti fún ara yín kọ́ ni ẹ̀yin mú bí?
Na canei awh nahaiyah ma ngainae patetlah vai na canei a vaw.
7 Wọ̀nyí kọ́ ni ọ̀rọ̀ ti Olúwa ti kígbe láti ọ̀dọ̀ àwọn wòlíì ìṣáájú wá, nígbà tí a ń gbé Jerusalẹmu, tí ó sì wà ní àlàáfíà, pẹ̀lú àwọn ìlú rẹ̀ tí ó yí i káàkiri, nígbà tí a ń gbé gúúsù àti pẹ̀tẹ́lẹ̀.’”
Jerusalem khopui hoi atengpam e khonaw akalae hoi tanghlingnaw dawk e tami apap lahun navah, ayan e profetnaw koe Cathut ni a pathang e kâlawk akuep toung nahoehmaw telah a ti.
8 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Sekariah wá, wí pé,
Hat navah, Zekhariah koe ka phat e BAWIPA e lawk teh,
9 “Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, ‘Ṣe ìdájọ́ òtítọ́, kí ẹ sì ṣe àánú àti ìyọ́nú olúkúlùkù sí arákùnrin rẹ̀.
Kalan lah lawkceng awh. Pahren lungmanae hoi buet touh hoi buet touh lungkâpataw awh.
10 Má sì ṣe ni opó lára tàbí aláìní baba, àlejò, tàbí tálákà; kí ẹnikẹ́ni nínú yín má ṣe gbèrò ibi ní ọkàn sí arákùnrin rẹ̀.’
Naranaw, lahmai napui, ayâ khoram kaawm e karoedengnaw rektap awh hanh. Buet touh hoi buet touh kahawihoehe pouknae tawn awh hanh telah ransahu BAWIPA ni a dei e teh,
11 “Ṣùgbọ́n wọ́n kọ̀ láti gbọ́, wọ́n sì gún èjìká, wọ́n sì pa ẹ̀yìn dà, wọ́n di etí wọn, kí wọn má ba à gbọ́.
Ahnimouh ni ka lawk ngai laipalah hlout nahanlah a kâyawm awh. A thai hoeh nahanlah a hnâ a tabuem awh.
12 Wọ́n sé ọkàn wọn bí òkúta líle, kí wọn má ba à gbọ́ òfin, àti ọ̀rọ̀ tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti fi ẹ̀mí rẹ̀ rán nípa ọwọ́ àwọn wòlíì ìṣáájú wá. Ìbínú ńlá sì dé láti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
Phunglawk thoseh, ransahu BAWIPA e Muitha niyah ayan e profetnaw koe a dei pouh e lawk thoseh, ahnimouh ni a thai awh hoeh nahanlah a lungthinnaw lungtaw patetlah a pata sak awh. Hatdawkvah, ransahu BAWIPA teh puenghoi a lungkhuek.
13 “‘Ó sì ṣe, gẹ́gẹ́ bí ó ti kígbe, tí wọn kò sì fẹ́ gbọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n kígbe, tí èmi kò sì fẹ́ gbọ́,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Kai ni ka kaw navah a thai awh hoeh e patetlah, ahnimouh ni na kaw to hai kai ni ka thai pouh mahoeh telah ransahu BAWIPA ni a ti.
14 ‘Mo sì fi ìjì tú wọn ká sí gbogbo orílẹ̀-èdè tí wọn kò mọ̀. Ilẹ̀ náà sì dahoro lẹ́yìn wọn, tí ẹnikẹ́ni kò là á kọjá tàbí kí ó padà bọ̀, wọ́n sì sọ ilẹ̀ ààyò náà dahoro.’”
Ahnimouh ni a panue awh hoeh e miphunnaw koevah bongparui hoi ka palek sak awh toe. Hatdawkvah, ahnimae ram teh kingkadi lah ao teh, apihaiyah kâhlumkâhlai e awm hoeh. Ram kahawi teh koung raphoe lah ao telah a ti.