< Zechariah 6 >

1 Mo sì yípadà, mo sì gbé ojú mi sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, kẹ̀kẹ́ mẹ́rin jáde wá láti àárín òkè ńlá méjì, àwọn òkè ńlá náà sì jẹ́ òkè ńlá idẹ.
Ningĩ ngĩtiira maitho rĩngĩ, na rĩrĩ, ngĩona ngaari inya cia ita igĩũka ciumĩte gatagatĩ ka irĩma igĩrĩ, irĩma icio ciarĩ cia gĩcango!
2 Àwọn ẹṣin pupa wà ní kẹ̀kẹ́ èkínní; àti àwọn ẹṣin dúdú ní kẹ̀kẹ́ èkejì.
Ngaari ya mbere yaguucĩtio nĩ mbarathi ndune, na ya keerĩ ĩkaguucio nĩ mbarathi njirũ,
3 Àti àwọn ẹṣin funfun ní kẹ̀kẹ́ ẹ̀kẹta; àti àwọn adíkálà àti alágbára ẹṣin ní kẹ̀kẹ́ ẹ̀kẹrin.
na ya gatatũ ĩkaguucio nĩ mbarathi njerũ, nayo ya kana ĩkaguucio nĩ mbarathi cia marooro; ciothe ciarĩ mbarathi ciarĩ na hinya.
4 Mo sì dáhùn, mo sì béèrè lọ́wọ́ angẹli tí ń bá mi sọ̀rọ̀ pé, “Kí ni ìwọ̀nyí, olúwa mi.”
Ngĩũria mũraika ũcio wanjaragĩria atĩrĩ, “Mwathi wakwa, ici nacio nĩ ndũũ?”
5 Angẹli náà si dáhùn ó sì wí fún mi pé, “Wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀mí mẹ́rin ti ọ̀run, tí wọn ń lọ kúrò lẹ́yìn tí wọ́n ti fi ara wọn hàn níwájú Olúwa gbogbo ayé.
Nake mũraika ũcio akĩnjookeria atĩrĩ, “Maya nĩ maroho marĩa mana ma igũrũ, maroima harĩa marũgamaga mbere ya Mwathani wa thĩ yothe.
6 Àwọn ẹṣin dúdú tí ó wà nínú rẹ̀ jáde lọ sí ilẹ̀ àríwá; àwọn funfun sì jáde lọ si ìwọ̀-oòrùn; àwọn adíkálà sì jáde lọ sí ìhà ilẹ̀ gúúsù.”
Ngaari ĩyo ĩguucĩtio nĩ mbarathi njirũ yerekeire bũrũri wa gathigathini, nayo ĩyo ĩguucĩtio nĩ mbarathi njerũ yerekeire bũrũri wa ithũĩro, nayo ĩyo ĩguucĩtio nĩ mbarathi irĩ na maroro yerekeire bũrũri wa gũthini.”
7 Àwọn alágbára ẹṣin sì jáde lọ, wọ́n sì ń wá ọ̀nà àti lọ kí wọn bá a lè rìn síyìn-ín sọ́hùn-ún ni ayé; ó sì wí pé, “Ẹ lọ, ẹ lọ rìn síyìn-ín sọ́hùn-ún ní ayé!” Wọ́n sì rín síyìn-ín sọ́hùn-ún ní ayé.
Rĩrĩa mbarathi icio irĩ hinya cioimagarire-rĩ, nĩciageragia mũno ũrĩa ingĩthiĩ thĩ yothe. Nake agĩciĩra atĩrĩ, “Thiĩi mũcange thĩ yothe!” Nĩ ũndũ ũcio igĩthiĩ thĩ yothe.
8 Nígbà náà ni ohùn kan sì ké sí mi, ó sì bá mi sọ̀rọ̀ wí pé, “Wò ó, àwọn wọ̀nyí tí ó lọ síhà ilẹ̀ àríwá ti mú ẹ̀mí mi parọ́rọ́ ni ilẹ̀ àríwá.”
Ningĩ agĩcooka akĩnjĩta akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Ta rora, icio cierekeire bũrũri wa gathigathini nĩitũmĩte Roho wakwa ũgĩe na ũhurũko kũu bũrũri wa gathigathini.”
9 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá, wí pé:
Ndũmĩrĩri ya Jehova nĩyanginyĩrire ngĩĩrwo atĩrĩ,
10 “Mú nínú ìgbèkùn, nínú àwọn Heldai, tí Tobiah, àti ti Jedaiah, tí ó ti Babeli dé, kí ìwọ sì wá ní ọjọ́ kan náà, kí o sì wọ ilé Josiah ọmọ Sefaniah lọ.
“Amũkĩra betha na thahabu kuuma kũrĩ andũ arĩa maatahĩtwo, na nĩo Helidai, na Tobija, na Jedaia, arĩa mokĩte kuuma Babuloni. Thiĩ o ũmũthĩ mũciĩ kwa Josia mũrũ wa Zefania.
11 Kí o sì mú fàdákà àti wúrà, kí o sì fi ṣe adé púpọ̀, sì gbé wọn ka orí Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà.
Oya betha na thahabu icio ũthondeke thũmbĩ, ũcooke ũmĩigĩrĩre mũtwe wa Joshua mũrũ wa Jehozadaki, mũthĩnjĩri-Ngai ũrĩa mũnene.
12 Sì sọ fún un pé, ‘Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ wí pé, wo ọkùnrin náà ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ẹ̀ka; yóò sì yọ ẹ̀ka láti abẹ́ rẹ̀ wá, yóò si kọ́ tẹmpili Olúwa wa.
Mwĩre atĩ Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga ũũ: ‘Ũyũ nĩwe mũndũ ũrĩa wĩtagwo Rũhonge, nake nĩakaruta honge arĩ handũ haake na ake hekarũ ya Jehova.
13 Òun ni yóò sì kọ́ tẹmpili Olúwa òun ni yóò sì wọ̀ ní ògo, yóò sì jókòó, yóò sì jẹ ọba lórí ìtẹ́ rẹ̀; òun ó sì jẹ́ àlùfáà lórí ìtẹ́ rẹ̀; ìmọ̀ àlàáfíà yóò sì wá láàrín àwọn méjèèjì.’
Ũcio nĩwe ũgaaka hekarũ ya Jehova, na nĩakahumbwo riiri, na nĩagaikarĩra gĩtĩ gĩake kĩa ũnene aathane. O na nĩagatungata arĩ mũthĩnjĩri-Ngai aikarĩire gĩtĩ gĩake kĩa ũnene; na maũndũ macio meerĩ nĩmakaganĩrĩra wega.’
14 Adé wọ̀nyí yóò sì wà fún Helemu àti fún Tobiah, àti fún Jedaiah, àti fún Heni ọmọ Sefaniah fún ìrántí ni tẹmpili Olúwa.
Nayo thũmbĩ ĩyo ĩigwo thĩinĩ wa hekarũ ya Jehova, ĩrĩ kĩririkano kĩa Helidai, na Tobija, na Jedaia, na Heni mũrũ wa Zefania.
15 Àwọn tí ó jìnnà réré yóò wá láti kọ́ tẹmpili Olúwa, ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti rán mi sí yín. Yóò sì rí bẹ́ẹ̀ bí ẹ̀yin yóò bá gbà ohùn Olúwa, Ọlọ́run yín gbọ́ nítòótọ́.”
Arĩa marĩ kũraya nĩmagooka gũteithia gwaka hekarũ ya Jehova, na inyuĩ nĩmũkamenya atĩ Jehova Mwene-Hinya-Wothe nĩwe ũndũmĩte kũrĩ inyuĩ. Ũndũ ũyũ nĩũgekĩka mũngĩgaathĩkĩra Jehova Ngai wanyu mũrĩ na kĩyo.”

< Zechariah 6 >