< Zechariah 6 >

1 Mo sì yípadà, mo sì gbé ojú mi sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, kẹ̀kẹ́ mẹ́rin jáde wá láti àárín òkè ńlá méjì, àwọn òkè ńlá náà sì jẹ́ òkè ńlá idẹ.
Ka mael tih ka mik ka huel tih ka sawt. Te vaengah rhohum tlang kah tlang neh tlang rhoi laklo lamloh leng pali tarha ha thoeng.
2 Àwọn ẹṣin pupa wà ní kẹ̀kẹ́ èkínní; àti àwọn ẹṣin dúdú ní kẹ̀kẹ́ èkejì.
Lamhma kah leng dongah marhang rhoek tah ling tih leng pabae dongah marhang rhoek tah muem.
3 Àti àwọn ẹṣin funfun ní kẹ̀kẹ́ ẹ̀kẹta; àti àwọn adíkálà àti alágbára ẹṣin ní kẹ̀kẹ́ ẹ̀kẹrin.
Leng a pathum dongah marhang rhoek tah bok tih leng a pali dongah marhang rhoek tah dikdek la lingduk.
4 Mo sì dáhùn, mo sì béèrè lọ́wọ́ angẹli tí ń bá mi sọ̀rọ̀ pé, “Kí ni ìwọ̀nyí, olúwa mi.”
Te dongah kai taengah aka cal puencawn te ka voek tih, “Ka boeipa aw, he rhoek balae?” ka ti nah.
5 Angẹli náà si dáhùn ó sì wí fún mi pé, “Wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀mí mẹ́rin ti ọ̀run, tí wọn ń lọ kúrò lẹ́yìn tí wọ́n ti fi ara wọn hàn níwájú Olúwa gbogbo ayé.
Te dongah puencawn loh n'doo tih kai taengah, “He tah diklai pum boeipa taengah aka pai lamloh aka thoeng vaan mueihla pali ni.
6 Àwọn ẹṣin dúdú tí ó wà nínú rẹ̀ jáde lọ sí ilẹ̀ àríwá; àwọn funfun sì jáde lọ si ìwọ̀-oòrùn; àwọn adíkálà sì jáde lọ sí ìhà ilẹ̀ gúúsù.”
Marhang muem rhoek he tah tlangpuei kho la aka cet ham tih, a bok rhoek he a hnuk la a khuen ham, dikdek rhoek he tah tuithim khohmuen la aka cet ham ni,” a ti.
7 Àwọn alágbára ẹṣin sì jáde lọ, wọ́n sì ń wá ọ̀nà àti lọ kí wọn bá a lè rìn síyìn-ín sọ́hùn-ún ni ayé; ó sì wí pé, “Ẹ lọ, ẹ lọ rìn síyìn-ín sọ́hùn-ún ní ayé!” Wọ́n sì rín síyìn-ín sọ́hùn-ún ní ayé.
Te vaengah a lingduk rhoek te coe uh tih diklai ah caeh ham neh pongpa hamla la cai uh. Te dongah, “Diklai ah cet khaw cet uh laeh,” a ti nah tih diklai ah pongpa uh.
8 Nígbà náà ni ohùn kan sì ké sí mi, ó sì bá mi sọ̀rọ̀ wí pé, “Wò ó, àwọn wọ̀nyí tí ó lọ síhà ilẹ̀ àríwá ti mú ẹ̀mí mi parọ́rọ́ ni ilẹ̀ àríwá.”
Te phoeiah kai te n'khue tih kai hamla han thui. Te vaengah, “Tlangpuei khohmuen la aka cet rhoek ke so lah, ka mueihla he tlangpuei khohmuen ah duem coeng,” a ti.
9 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá, wí pé:
BOEIPA ol te kai taengla pai tih,
10 “Mú nínú ìgbèkùn, nínú àwọn Heldai, tí Tobiah, àti ti Jedaiah, tí ó ti Babeli dé, kí ìwọ sì wá ní ọjọ́ kan náà, kí o sì wọ ilé Josiah ọmọ Sefaniah lọ.
“Vangsawn taeng lamkah, Heldai lamkah neh Tobiah taeng lamkah khaw, Jedaiah taeng lamkah khaw khuen laeh. Amah hnin ah namah cet laeh. Babylon lamkah aka pai Zephaniah capa Josiah im te paan laeh,” a ti.
11 Kí o sì mú fàdákà àti wúrà, kí o sì fi ṣe adé púpọ̀, sì gbé wọn ka orí Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà.
Sui neh cak te lo lamtah rhuisam saii laeh. Te phoeiah khosoih puei Jehozadak capa Joshua lu ah khuem sak.
12 Sì sọ fún un pé, ‘Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ wí pé, wo ọkùnrin náà ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ẹ̀ka; yóò sì yọ ẹ̀ka láti abẹ́ rẹ̀ wá, yóò si kọ́ tẹmpili Olúwa wa.
Te phoeiah anih taengah te thui pah lamtah, ‘Caempuei BOEIPA loh he ni a thui, “Hlang he a ming thingdawn” ti nah.’ “‘A hmui lamloh poe vetih BOEIPA bawkim te a sak ni.
13 Òun ni yóò sì kọ́ tẹmpili Olúwa òun ni yóò sì wọ̀ ní ògo, yóò sì jókòó, yóò sì jẹ ọba lórí ìtẹ́ rẹ̀; òun ó sì jẹ́ àlùfáà lórí ìtẹ́ rẹ̀; ìmọ̀ àlàáfíà yóò sì wá láàrín àwọn méjèèjì.’
Amah loh BOEIPA bawkim te a sak ni. Anih te mueithennah a phueih ni. A ngolkhoel dongah ngol vetih a taemrhai ni. A ngolkhoel dongah khosoih la om vetih amih rhoi laklo ah rhoepnah cilsuep om ni.
14 Adé wọ̀nyí yóò sì wà fún Helemu àti fún Tobiah, àti fún Jedaiah, àti fún Heni ọmọ Sefaniah fún ìrántí ni tẹmpili Olúwa.
Te vaengah rhuisam te Helen taeng neh Tobiah taengah khaw, Jedaiah taeng neh Zephaniah capa Khen taengah khaw BOEIPA bawkim ah poekkoepnah la om ni.
15 Àwọn tí ó jìnnà réré yóò wá láti kọ́ tẹmpili Olúwa, ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti rán mi sí yín. Yóò sì rí bẹ́ẹ̀ bí ẹ̀yin yóò bá gbà ohùn Olúwa, Ọlọ́run yín gbọ́ nítòótọ́.”
Khohla rhoek khaw ha pai uh vetih BOEIPA bawkim te a sak uh ni. Te vaengah caempuei BOEIPA loh nangmih taengla kai n'tueih te na ming uh bitni. Na Pathen BOEIPA ol te na hnatun la na hnatun uh atah thoeng bitni,’ ti nah,” a ti.

< Zechariah 6 >